Publicidade

Jeremias 15

1 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún mi : "Kódà Mose àti Samuẹli dúró níwájú mi, ọkàn mi yóò lọ sọ́dọ̀ àwọn ènìyàn wọ̀nyí. wọn kúrò níwájú mi! Jẹ́ wọn ó lọ! 2 15.2: If 13.10.wọ́n bi ́ , Níbo ni a lọ?Sọ fún wọn , Báyìí ni Olúwa :

" Àwọn a kọ ikú mọ́, ikú;

àwọn a kọ idà mọ́, idà;

àwọn a kọ ìyàn mọ́, ìyàn;

àwọn a kọ ìgbèkùn mọ́ ìgbèkùn.

3 "Èmi yóò rán oríṣìí ìjìyà mẹ́rin láti kọlù wọ́n," ni Olúwa , "Idà láti pa, àwọn ajá láti wọ́ wọn lọ, àwọn ẹyẹ ojú ̀run àti àwọn ẹranko orí ilẹ̀ láti jẹ àti láti parun. 4 N ó sọ wọ́n di ẹni ìkórìíra níwájú gbogbo ìjọba ayé torí ohun Manase ọmọ Hesekiah ọba Juda ṣe Jerusalẹmu.

5 "Ta ni yóò ṣàánú rẹ, ìwọ Jerusalẹmu?

Ta ni yóò dárò rẹ?

Ta ni yóò dúró béèrè àlàáfíà rẹ?

6 O ti kọ̀ sílẹ̀," ni Olúwa ,

"Ìwọ nínú ìpadàsẹ́yìn.

Nítorí náà, Èmi yóò dáwọ́, èmi ó pa ́ run,

Èmi fi ojú àánú ́ mọ́.

7 Èmi tún fi ìfẹ́ hàn si ,

Èmi yóò fi àtẹ fẹ́ wọn ẹnu-ọ̀ìlú náà.

Èmi yóò ìṣọ̀fọ̀ àti ìparun

àwọn ènìyàn mi nítorí wọn

ì yípadà kúrò lọ́wọn.

8 Èmi yóò jẹ́ àwọn opó wọn pọ̀ ju

yanrìn Òkun lọ.

ọjọ́-kanrí ni èmi ó apanirun

kọlu àwọn ìyá ọmọkùnrin wọn.

Lójijì ni èmi yóò

ìfòyà àti ìbẹ̀wọn.

9 Ìyá ọlọ́mọ méje yóò dákú,

yóò ìmí ìgbẹ̀yìn.

Òòrùn rẹ yóò wọ̀ lọ́sàn án gangan,

yóò di ẹni ̀tẹ́ òun àbùkù.

Èmi yóò fi àwọn ó síwájú

àwọn ̀wọn idà lọ́wọ́ wọn,"

ni Olúwa .

10 Háà! Ó ṣe ìyá mi mi,

ọkùnrin gbogbo ilẹ̀ dojúkọ wọ́n !

Èmi wínni, bẹ́̀ ni èmi lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni,

síbẹ̀, gbogbo ènìyàn ń fi .

11 Olúwa sọ ,

"Dájúdájú èmi ò fún ìdí kan pàtó;

dájúdájú mo àwọn ̀rẹ tẹríba níwájú rẹ

nígbà ibi àti ìpọ́njú.

12 "Ǹjẹ́ ẹnìkan fi ọwọ́ ṣẹ́ irin

irin láti àríwá tàbí idẹ?

13 "Gbogbo ọlá àti ìṣúra rẹ

ni èmi ó fi sílẹ̀ gẹ́gẹ́ ìkógun láìgba

nǹkan kan nítorí gbogbo ̀ṣẹ̀ rẹ

jákèjádò orílẹ̀-èdè rẹ.

14 Èmi yóò fi ́ ṣẹrú fún àwọn ̀rẹ

ìlú ìwọ mọ̀ nítorí ìbínú

mi yóò rán iná yóò ."

15 Ó , ìwọ Olúwa;

rántí mi o ṣe ìtọ́mi.

Gbẹ̀san mi lára àwọn dìtẹ̀ mi.

Ìwọ ti jìyà fún ìgbà pípẹ́, ṣe mi lọ;

nínú mo ṣe jìyà nítorí tìrẹ.

16 Nígbà ̀rọ̀ rẹ , mo jẹ wọ́n,

àwọn ni ìdùnnú àti ayọ̀ ọkàn mi,

nítorí orúkọ rẹ ni a fi ń ,

Ìwọ Olúwa Ọlọ́run Alágbára.

17 Èmi fìgbà kan jókòó láàrín àwọn ẹlẹ́gàn,

n ko wọn yọ ayọ̀ pọ̀;

mo jókòó torí ọwọ́ rẹ lára mi,

ìwọ ti fi ìbínú rẹ kún inú mi.

18 Èéṣe ìrora mi lópin,

ọgbẹ́ mi ṣe é wòsàn?

òtítọ́ ìwọ yóò dàbí kànga ̀tàn mi,

gẹ́gẹ́ ìsun kọ̀ sun?

19 Nítorí náà báyìí ni Olúwa ,

"o ronúpìwàdà, Èmi ó padà

o máa sìn ;

ó sọ ̀rọ̀ dára,

ìwọ yóò di agbẹnusọ mi.

Jẹ́ àwọn ènìyàn yìí kọjú ;

ṣùgbọ́n ìwọ gbọdọ̀ kọjú wọn.

20 Èmi fi ́ ṣe odi idẹ ó lágbára,

àwọn ènìyàn wọ̀nyí;

wọn ó

ṣùgbọ́n wọn borí rẹ,

nítorí , mo pẹ̀rẹ

láti gbà ́ , n dáàbò ́,"

ni Olúwa .

21 "Èmi yóò gbà ́ sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ìkà ènìyàn,

Èmi yóò ́ padà kúrò lọ́wọ́ àwọn ẹni búburú."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-