Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremias 23

̀ka òtítọ́

1 "Ègbé ni fún àwọn olùṣọ́-àgùntàn ń agbo ẹran mi ó ń pa wọ́n run!" ni Olúwa . 2 Nítorí náà, èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run Israẹli sọ ti àwọn olùṣọ́-àgùntàn ń darí àwọn ènìyàn mi: "Nítorí ̀yin agbo ẹran mi , wọn dànù ̀yin bẹ̀ wọ́n . Èmi yóò jẹ yín nítorí nǹkan búburú ti ṣe," ni Olúwa . 3 "Èmi Olúwa tìkára mi yóò ìyókù agbo ẹran mi jọ láti inú gbogbo orílẹ̀-èdè mo ti wọn, Èmi yóò wọn padà sínú pápá oko wọn, níbẹ̀ ni wọn ó ti i, wọn ó pọ̀ i. 4 Èmi ó olùṣọ́-àgùntàn fún wọn, yóò darí wọn, wọn yóò bẹ̀tàbí dààmú, bẹ́̀ ni ̀kan yóò sọnù," ni Olúwa .

5 23.5: Jr 33.15; Isa 4.2; Sk 3.8; 6.12. "Ọjọ́ ń bọ̀," ni Olúwa ,

"Èmi yóò gbé ̀ka òdodo dìde fún Dafidi,

ọba yóò lo ìjọba pẹ̀ọgbọ́n

yóò ṣe òdodo àti ohun ó yẹ lórí ilẹ̀ náà.

6 ọjọ́ rẹ̀ ni a ó gba Juda ,

Israẹli yóò máa gbé aláìléwu.

Èyí ni orúkọ a ó fi máa é:

Olúwa Òdodo wa.

7 Nítorí náà, ọjọ́ ń bọ̀," ni Olúwa , "ènìyàn yóò tún , Dájúdájú Olúwa láààyè ó àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ilẹ̀ Ejibiti.8 Ṣùgbọ́n wọn yóò máa , Dájúdájú Olúwa ń bẹ ó irú-ọmọ ilé Israẹli láti ilẹ̀ àríwá àti láti àwọn ilẹ̀ ibi mo wọn lọ,wọn ó gbé inú ilẹ̀ wọn."

Àwọn wòlíì èké

9 Nípa ti àwọn wòlíì èké.

Ọkàn mi ti bàjẹ́ nínú mi,

gbogbo egungun mi ni ó wárìrì.

Èmi dàbí ̀mùtí ènìyàn,

ọkùnrin ọtí wáìnì ń pa;

nítorí Olúwa àti àwọn ̀rọ̀ mímọ́ rẹ̀.

10 Ilẹ̀ náà kún fún panṣágà ènìyàn;

nítorí ègún, ilẹ̀ náà gbẹ,

àwọn koríko orí aṣálẹ̀ ilẹ̀ náà rọ.

Àwọn wòlíì tẹ̀̀búburú,

wọ́n ń lo agbára wọn lọ́àìtọ́.

11 "Wòlíì àti àlùfáà gbé ìgbé ayé ìwà-bí-Ọlọ́run;

kódà nínú tẹmpili mi ni mo ìwà búburú wọn,"

ni Olúwa .

12 "Nítorí náà, ̀wọn yóò di yíyọ́,

a ó wọn jáde sínú òkùnkùn;

níbẹ̀ ni wọn yóò ṣubú.

Èmi yóò ìdààmú sórí wọn,

ọdún a jẹ wọ́n ìyà,"

ni Olúwa .

13 "Láàrín àwọn wòlíì Samaria,

Èmi ohun ń ni .

Wọ́n sọ àsọtẹ́lẹ̀ lórúkọ Baali

wọ́n Israẹli ènìyàn mi ṣìnà.

14 Àti láàrín àwọn wòlíì Jerusalẹmu,

èmi ti ohun búburú.

Wọ́n ṣe panṣágà, wọ́n ń ṣèké.

Wọ́n fún àwọn olùṣe búburú agbára,

bẹ́̀ ẹnìkan ó yípadà kúrò nínú ìwà búburú rẹ̀.

Gbogbo wọn dàbí Sodomu níwájú mi,

àti àwọn ènìyàn olùgbé rẹ̀ Gomorra."

15 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Ọlọ́run Alágbára ti àwọn wòlíì:

"Èmi yóò wọn jẹ oúnjẹ kíkorò,

wọn yóò mu omi májèlé

nítorí láti ̀dọ̀ àwọn wòlíì Jerusalẹmu

ni àìwà-bí-Ọlọ́run ti tàn gbogbo ilẹ̀."

16 Èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun :

"ṣe fi etí àsọtẹ́lẹ̀ àwọn wòlíì èké ń sọ fún un yín.

Wọ́n ń kún inú ọkàn yín pẹ̀ìrètí asán.

Wọ́n ń sọ ìran láti ọkàn ara wọn,

í ṣe láti ẹnu Olúwa.

17 Wọ́n ń sọ fún àwọn ó ń gàn ,

Olúwa ti , ̀yin ó àlàáfíà.

Wọ́n fún gbogbo àwọn ó rìn nípa agídí ọkàn rẹ̀ ,

ìpalára kan yóò ṣẹlẹ̀ yín.

18 Ṣùgbọ́n èwo nínú wọn ni ó dúró

nínú ìgbìmọ̀ Olúwa láti i

tàbí gbọ́ ̀rọ̀ rẹ̀?

Ta ni ó gbọ́ ó fetí ̀rọ̀ náà?

19 ó, afẹ́fẹ́ Olúwa yóò jáde

pẹ̀ìbínú à fẹ́ yíká ìjì yóò fẹ́

orí àwọn olùṣe búburú.

20 Ìbínú Olúwa yóò yẹ̀

títí yóò fi èrò rẹ̀ ṣẹ,

àìpẹ́ ọjọ́, yóò e yín yékéyéké.

21 Èmi rán àwọn wòlíì wọ̀nyí

síbẹ̀ wọ́n lọ pẹ̀̀rọ̀ wọn.

Èmi tilẹ̀ wọn sọ̀rọ̀,

síbẹ̀ wọ́n sọ àsọtẹ́lẹ̀.

22 Ṣùgbọ́n ì ṣe wọn dúró nínú ìgbìmọ̀ mi,

wọn ìbá ti kéde ̀rọ̀ mi fún àwọn ènìyàn mi.

Wọn ìbá ti wàásù ̀rọ̀ mi fun àwọn ènìyàn

wọn ìbá ti yípadà kúrò nínú ̀

àti ìṣe búburú wọn.

23 "Ǹjẹ́ Ọlọ́run tòsí nìkan ni Èmi ?"

ni Olúwa ,

"í í ṣe Ọlọ́run ̀jíjìn.

24 Ǹjẹ́ ẹnikẹ́ni pamọ́ ibi kọ́lọ́fín kan,

èmi ba a ?"

ni Olúwa .

"Ǹjẹ́ èmi ha a kún ̀run àti ayé ?"

ni Olúwa .

25 "Mo ti gbọ́ gbogbo ohun àwọn wòlíì èké ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ orúkọ mi ń sọ. Wọ́n sọ , Mo àlá! Mo àlá!26 Títí di ìgbà wo ni èyí yóò fi máa tẹ̀síwájú ni ọkàn àwọn wòlíì èké wọ̀nyí wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ ìtànjẹ ọkàn wọn? 27 Wọ́n àlá wọ́n ń sọ fún ara wọn yóò àwọn ènìyàn mi gbàgbé orúkọ mi, gẹ́gẹ́ àwọn baba wọn ṣe gbàgbé orúkọ mi nípa sin òrìṣà Baali. 28 Jẹ́ wòlíì ó àlá sọ àlá rẹ̀, ṣùgbọ́n jẹ́ ẹni ó ̀rọ̀ sọ ́ òtítọ́. ni koríko gbígbẹ í ṣe nínú ọkà?" ni Olúwa . 29 "̀rọ̀ mi ha a dàbí iná?" ni Olúwa , "àti òòlù irin ń fọ́ àpáta túútúú?

30 "Nítorí náà, èmi lòdì àwọn wòlíì ni," Olúwa , "ń ̀rọ̀ ó yẹ ó ti ̀dọ̀ mi lọ́dọ̀ ara wọn. 31 Bẹ́̀," ni Olúwa , "Èmi lòdì àwọn wòlíì wọ́n lo ahọ́n wọn káàkiri, síbẹ̀ wọ́n ń sọ , Olúwa .32 Nítòótọ́, mo lòdì àwọn ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa àlá èké," ni Olúwa . "Wọ́n ń sọ bẹ́̀ ni wọ́n ń àwọn ènìyàn mi ṣìnà nípa onírúurú èké wọn, síbẹ̀ èmi rán wọn tàbí yàn wọ́n. Wọn ran àwọn ènìyàn wọ̀nyí lọ́wọ́ ó ti ó kéré mọ," ni Olúwa .

̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ èké àti àwọn wòlíì èké

33 "Nígbà àwọn ènìyàn wọ̀nyí, tàbí wòlíì tàbí àlùfáà bi ́ léèrè , ni ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa?Sọ fún wọn , ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ wo? Èmi yóò pa yín ni Olúwa .34 wòlíì tàbí àlùfáà tàbí ẹnikẹ́ni gbà , Èyí ni ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa.Èmi yóò fi ìyà jẹ ọkùnrin náà àti gbogbo agbo ilé rẹ̀. 35 Èyí ni ohun ẹnìkọ̀̀kan yín ń sọ fún ̀rẹ́ àti ará ilé rẹ̀: ni ìdáhùn Olúwa?Tàbí ni ohun Olúwa sọ?36 Ṣùgbọ́n ̀yin gbọdọ̀ dárúkọ ̀rọ̀ ìjìnlẹ̀ Olúwamọ́, nítorí ̀rọ̀ oníkálùkù ènìyàn di ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ rẹ̀. Nítorí náà, ̀yin ń ̀rọ̀ Ọlọ́run alààyè, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run wa padà. 37 Èyí ni ohun ̀yin ń sọ fún wòlíì: ni ìdáhùn Olúwa ́?’ Tàbí ni ohun Olúwa sọ?38 ó tilẹ̀ jẹ́ ̀yin ń sọ , Èyí ni ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa,èyí ni ohun Olúwa sọ, ̀yin ń lo ̀rọ̀ yìí, Èyí ni ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa,ó tilẹ̀ jẹ́ mo sọ fún un yín láti ṣe ó mọ́, Èyí ni ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa.39 Nítorí náà, Èmi yóò gbàgbé yín, bẹ́̀ ni n ó e yín kúrò níwájú mi pẹ̀àwọn ìlú mo fi fún un yín àti àwọn baba yín. 40 Èmi yóò ìtìjú ayérayé orí yín, ìtìjú ìgbàgbé."

Veja também