Publicidade

Jeremias 31

31 31.31: Lk 22.20; 1Kọ 11.25. 31.31-34: Jr 32.38-40; Hb 8.8-12; 10.16-17. "Ìgbà kan ń bọ̀," ni Olúwa ,

"Èmi yóò ilé Israẹli

àti ilé Juda májẹ̀tuntun.

32 dàbí májẹ̀

mo àwọn baba ńlá wọn ,

nígbà mo wọ́n lọ́wọ́,

mo wọn jáde Ejibiti

nítorí wọ́n da májẹ̀mi.

Lóòótọ́ ọkọ ni èmi jẹ́ fún wọn,"

ni Olúwa .

33 "Èyí ni májẹ̀èmi yóò ilé Israẹli

lẹ́yìn ìgbà náà," ni Olúwa :

"Èmi yóò fi òfin mi ọkàn wọn,

èmi ó kọ ́ àyà wọn.

Èmi ó jẹ́ Olúwa wọn;

àwọn ó jẹ́ ènìyàn mi.

34 ọkùnrin kan ń kọ́ àwọn ará ilé rẹ̀

tàbí ọkùnrin ń kọ́ arákùnrin rẹ̀ , mọ Olúwa,

nítorí gbogbo wọn ni yóò mọ̀

láti ẹni kékeré wọn títí ẹni ńlá,"

ni Olúwa .

"Nítorí èmi ó dárí àìṣedéédéé wọn ,

èmi rántí ̀ṣẹ̀ wọn mọ́."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-