Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremias 18

2 "Sọ̀kalẹ̀ lọ ilé amọ̀kòkò, níbẹ̀ ni èmi yóò ti sọ̀rọ̀." 3 Nígbà náà ni mo lọ ilé amọ̀kòkò mo i ó ń ṣiṣẹ́ kan lórí kẹ̀kẹ́. 4 Ṣùgbọ́n ìkòkò ó ń mọ láti ara amọ̀ bàjẹ́ ọwọ́ rẹ̀, nítorí náà ni amọ̀kòkò fi ṣe ìkòkò mìíràn, ó mọ ́n èyí ó dára ojú rẹ̀.

5 Nígbà náà ni ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 6 18.6: Ro 9.21."Ẹyin ilé Israẹli, èmi ha ṣe fún un yín gẹ́gẹ́ amọ̀kòkò yìí ti ṣe?" ni Olúwa . "Gẹ́gẹ́ amọ̀ ọwọ́ amọ̀kòkò bẹ́̀ ni ̀yin ọwọ́ mi, ̀yin ilé Israẹli.

Veja também