Publicidade

Jeremias 17

1 "̀ṣẹ̀ Juda ni a fi kálámù irin kọ,

èyí a fi ṣóńṣó òkúta adamante gbẹ́ ,

sórí wàláà oókan àyà wọn,

àti sórí ìwo pẹpẹ yín.

2 Kódà àwọn ọmọ wọn rántí pẹpẹ

àti ère Aṣerah lẹ́bàá igi ó tẹ́ rẹrẹ

àti àwọn òkè gíga.

3 Àwọn òkè nínú ilẹ̀ àti àwọn ọrọ̀ rẹ̀

àti ọlá rẹ̀ ni èmi yóò fi sílẹ̀ ìjẹ

pẹ̀àwọn ibi gíga, nítorí ̀ṣẹ̀ ó

pọ̀ káàkiri orílẹ̀-èdè yín.

4 Láti ipasẹ̀ àìṣedéédéé yín ni ̀yin

yóò ti sọ ogún mo fún un yín .

Èmi yóò fi yín fún ̀yín ẹrú

ilẹ̀ ̀yin mọ̀,

nítorí ̀yin ti inú mi,

èyí yóò títí ayé."

5 Báyìí ni Olúwa :

"Ègbé ni fún àwọn ó fi ìgbẹ́kẹ̀wọn sínú ènìyàn,

ó fi agbára rẹ̀ sínú ẹran-ara,

àti ọkàn rẹ̀ lọ́dọ̀ Olúwa.

6 Yóò dàbí igbó ó ilẹ̀ aláìlọ́ràá,

ìre, nígbà ó ,

yóò máa gbé ibi ìyàngbẹ ilẹ̀ aginjù,

ilẹ̀ iyọ̀ ẹnikẹ́ni gbé.

7 "Ṣùgbọ́n ìbùkún ni fún ọkùnrin

náà ó gbẹ́kẹ̀Olúwa, ó fi

Olúwa ṣe ìgbẹ́kẹ̀rẹ̀.

8 Yóò dàbí igi a gbìn ipadò

ó ta gbòǹgbò rẹ̀ etí odò

ìbẹ̀fún un nígbà ooru,

gbogbo ìgbà ni èwe rẹ̀ máa ń tutù

ìjayà fún un ọdún ̀

bẹ́̀ ni dẹ́kun láti máa so èso."

9 Ọkàn ènìyàn kún fún ̀tàn ju ohun gbogbo lọ,

ó kọjá ohun a wòsàn.

Ta ni èyí ?

10 "Èmi Olúwa ń wo ọkàn

àti èrò inú ọmọ ènìyàn,

láti san èrè iṣẹ́ rẹ̀ fún un gẹ́gẹ́ ̀rẹ̀,

àti gẹ́gẹ́ iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀."

11 àparò pa ẹyin

ni ọmọ ènìyàn ó ọrọ̀ jọ ni ̀àìṣòdodo.

Yóò di ẹni ìkọ̀sílẹ̀ agbede-méjì ayé rẹ̀,

àti òpin rẹ̀ yóò di aṣiwèrè.

12 Ìtẹ́ ògo; ibi gíga láti ìpilẹ̀ṣẹ̀

ibi ilé mímọ́ wa.

13 Olúwa ìwọ ni ìrètí Israẹli;

gbogbo àwọn ó kọ̀ ́ sílẹ̀ ni ojú ó .

Àwọn ó padà sẹ́yìn kúrò lọ́dọ̀ rẹ

ni a ó kọ orúkọ wọn sínú ekuru,

nítorí wọ́n ti kọ Olúwa,

orísun omi ìyè sílẹ̀.

14 sàn Olúwa, èmi yóò di ẹni ìwòsàn,

gbà , èmi yóò di ẹni ìgbàlà,

nítorí ìwọ ni ìyìn mi.

15 Wọ́n sọ fún mi :

"Níbo ni ̀rọ̀ Olúwa ?

Jẹ́ ó di ìmúṣẹ báyìí."

Ni Olúwa .

16 Èmi kúrò láti máa jẹ́ olùṣọ àgùntàn rẹ,

ìwọ mọ̀ èmi kẹ̀rẹ̀ ọjọ́ ìpọ́njú.

Ohun ó jáde ètè mi jẹ́ èyí ó hàn .

17 ṣe di ìbẹ̀fún mi,

ìwọ ni ààbò mi ọjọ́ ìpọ́njú.

18 Jẹ́ ojú ti àwọn ẹni ń lépa mi,

ṣùgbọ́n pa mọ́ kúrò nínú ìtìjú,

jẹ́ wọn ó dààmú.

ọjọ́ ibi sórí wọn,

fi ìparun ìlọ́po méjì pa wọ́n run.

Pípa ọjọ́ ìsinmi mọ́

19 Èyí ni ohun Olúwa fún mi: "Lọ dúró ẹnu-ọ̀àwọn ènìyàn níbi àwọn ọba Juda ń gbà wọlé wọ́n ń gbà jáde àti gbogbo ẹnu-bodè Jerusalẹmu. 20 Sọ fún wọ́n , gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa ̀yin ọba Juda àti gbogbo ̀yin ènìyàn Juda àti gbogbo ̀yin ń gbé Jerusalẹmu ń wọlé láti ẹnu ibodè yìí. 21 Báyìí ni Olúwa , "kíyèsi láti máa ru ẹrù lọ́jọ́ ìsinmi tàbí gbé wọlé láti ẹnu ibodè Jerusalẹmu. 22 ṣe gbé ẹrù jáde kúrò nínú ilé yín, bẹ́̀ ni ṣe ṣe iṣẹ́kíṣẹ́ ọjọ́ ìsinmi ṣùgbọ́n pa ọjọ́ ìsinmi mọ́ fún àwọn baba ńlá yín." 23 Síbẹ̀ wọn gbọ́ tàbí tẹ́sílẹ̀, wọ́n jẹ́ ọlọ́rùn líle; wọn í fẹ́ gbọ́ tàbí gba ìbáwí. 24 Ṣùgbọ́n ̀yin kíyèsi láti gbọ́ tèmi Olúwa , gbe ẹrù gba ẹnu-bodè ìlú ọjọ́ ìsinmi, ṣùgbọ́n ya ọjọ́ ìsinmi, mímọ́, nípa ṣe iṣẹ́kíṣẹ́ ọjọ́ náà. 25 Nígbà náà ni ọba ó jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi yóò gba ẹnu ibodè wọlé pẹ̀àwọn ìjòyè rẹ̀. Àwọn àti ìjòyè wọn yóò gun ẹṣin àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ , àwọn ọkùnrin Juda àti àwọn olùgbé Jerusalẹmu yóò tẹ̀wọn; ìlú yìí yóò di ibi gbígbé títí láéláé. 26 Àwọn ènìyàn yóò láti ìlú Juda àti agbègbè Jerusalẹmu, láti ilẹ̀ Benjamini, láti pẹ̀tẹ́lẹ̀, àti láti òkè, àti láti gúúsù , wọn yóò pẹ̀ọrẹ ẹbọ sísun, àti ọrẹ ẹran, àti tùràrí, àti àwọn ìyìn ilé Olúwa. 27 Ṣùgbọ́n ̀yin pa òfin mi mọ́ láti ya ọjọ́ ìsinmi mímọ́, ṣe ru ẹrùkẹ́̀yin yóò ṣe máa gba ẹnu ibodè Jerusalẹmu wọlé ọjọ́ ìsinmi, nígbà náà ni èmi yóò da iná ṣe é parun ẹnu-bodè Jerusalẹmu yóò odi agbára rẹ̀.’ "

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-