Publicidade

Jeremias 25

Àádọ́rin ọdún nínú oko ẹrú

1 ̀rọ̀ tọ Jeremiah nípa àwọn ènìyàn Juda ọdún kẹrin Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda, èyí ó jẹ́ ọdún kìn-ín-ní Nebukadnessari ọba Babeli. 2 Nítorí náà, Jeremiah wòlíì sọ fún gbogbo àwọn ènìyàn Juda àti àwọn olùgbé Jerusalẹmu. 3 Fún odidi ọdún mẹ́tàlélógún, bẹ̀rẹ̀ láti ọdún kẹtàlá Josiah, ọmọ Amoni ọba Juda, títí di ọjọ́ yìí, ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ , mo ti sọ ́ fún un yín láti ìgbà ìgbà, ṣùgbọ́n ̀yin fetísílẹ̀.

4 ó tilẹ̀ jẹ́ Olúwa ti rán gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, àwọn wòlíì i yín láti ìgbà ìgbà, ̀yin fetísílẹ̀. 5 Wọ́n , "yípadà olúkúlùkù yín kúrò inú ibi rẹ̀ àti ̀ibi rẹ̀, ̀yin yóò dúró ilẹ̀ Olúwa fún un yín àti àwọn baba yín títí láéláé. 6 ṣe tọ àwọn ọlọ́run mìíràn lẹ́yìn láti sìn wọ́n tàbí bọ wọ́n; ṣe inú mi pẹ̀ohun ti fi ọwọ́ yín ṣe. Nígbà náà ni Èmi ṣe yín ibi."

7 "Ṣùgbọ́n ̀yin fetí mi," ni Olúwa ; "bẹ́̀ ni ti inú mi pẹ̀ohun fi ọwọ́ yín ṣe, ti ibi sórí ara yín."

8 Nítorí náà, Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ èyí: "Nítorí ̀yin fetí ̀rọ̀ mi, 9 Èmi yóò pe gbogbo àwọn ènìyàn àríwá, àti ìránṣẹ́ mi Nebukadnessari ọba Babeli," ni Olúwa . "Èmi yóò wọn dìde lòdì ilẹ̀ náà àti àwọn olùgbé rẹ̀ àti gbogbo orílẹ̀-èdè àyíká rẹ̀. Èmi yóò pa wọ́n run pátápátá, Èmi yóò sọ wọ́n di nǹkan ̀àti yẹ̀yẹ́ àti ìparun ayérayé. 10 Èmi yóò ìró ayọ̀ àti inú dídùn kúrò lọ́dọ̀ wọn; ohùn ìyàwó àti ọkọ ìyàwó, ìró ọlọ òkúta àti ìmọ́lẹ̀ fìtílà. 11 Gbogbo orílẹ̀-èdè yìí yóò di ahoro, orílẹ̀-èdè yìí yóò sìn ọba Babeli àádọ́rin ọdún.

12 "Ṣùgbọ́n, nígbà àádọ́rin ọdún náà , Èmi yóò fi ìyà jẹ ọba Babeli àti orílẹ̀-èdè rẹ, ilẹ̀ àwọn ará Babeli nítorí ̀ṣẹ̀ wọn," ni Olúwa ; "bẹ́̀ ni Èmi yóò sọ ́ di ahoro títí láé. 13 Èmi yóò gbogbo ohun mo ti sọ wọ̀nyí sórí ilẹ̀ náà, gbogbo ohun a ti sọ àní gbogbo èyí a ti kọ sínú ìwé yìí, èyí Jeremiah ti sọtẹ́lẹ̀ gbogbo orílẹ̀-èdè. 14 Àwọn fúnra wọn yóò sin orílẹ̀-èdè púpọ̀ àti àwọn ọba ńlá. Èmi yóò sán fún oníkálùkù gẹ́gẹ́ ìṣe àti iṣẹ́ ọwọ́ wọn."

Ago ìbínú Ọlọ́run

15 Èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run Israẹli fún mi: "Gba ago yìí ọwọ́ ó kún fún ọtí wáìnì ìbínú mi, o gbogbo orílẹ̀-èdè ti mo rán mu ún. 16 Nígbà wọ́n mu ún, wọn yóò ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n: bẹ́̀ ni wọ́n di aṣiwèrè nítorí idà yóò ránṣẹ́ àárín wọn." 17 Mo gba ago náà lọ́wọ́ Olúwa, bẹ́̀ ni mo gbogbo orílẹ̀-èdè ó rán mi mu ún.

18 Jerusalẹmu àti àwọn ìlú Juda, àwọn ọba wọn pẹ̀àwọn aláṣẹ wọn, láti sọ wọ́n di ohun ìparun, ohun ̀, ̀sìn àti ègún, gẹ́gẹ́ wọ́n ti lónìí yìí.

19 Farao ọba Ejibiti, àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, àwọn aláṣẹ rẹ̀ àti àwọn ènìyàn rẹ̀. 20 Àti gbogbo àwọn ènìyàn àjèjì ó níbẹ̀;

gbogbo àwọn ọba Usi,

gbogbo àwọn ọba Filistini, gbogbo àwọn ti Aṣkeloni, Gasa, Ekroni àti gbogbo àwọn ènìyàn ó Aṣdodu.

21 Edomu, Moabu àti Ammoni;

22 gbogbo àwọn ọba Tire àti Sidoni;

gbogbo àwọn ọba erékùṣù wọ̀n-ọn-nì ń bẹ ìkọjá Òkun.

23 Dedani, Tema, Busi àti gbogbo àwọn ń gbé lọ́jíjìn réré.

24 Gbogbo àwọn ọba Arabia àti àwọn ọba àwọn àjèjì ènìyàn ń gbé inú aginjù.

25 Gbogbo àwọn ọba Simri, Elamu àti Media.

26 Àti gbogbo àwọn ọba àríwá tòsí àti lọ́jíjìn, ẹnìkínní lẹ́yìn ẹnìkejì; gbogbo àwọn ìjọba lórí orílẹ̀ ayé.

Àti gbogbo wọn, ọba Ṣeṣaki náà yóò mu.

27 "Nígbà náà, sọ fún wọn, èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run Alágbára Israẹli . Mu, o àmuyó o , bẹ́̀ ni o ṣubú láì dìde mọ́ nítorí idà n ó rán àárín yín. 28 Ṣùgbọ́n wọ́n ba kọ̀ láti gba ago náà ọwọ́ rẹ wọ́n mu ún, sọ fún wọn , Èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ: Ẹyin gbọdọ̀ mu ún! 29 ó, èmi ń ibi bọ̀ orí orílẹ̀-èdè ó ń jẹ́ orúkọ mi; ǹjẹ́ yóò ha a lọ láìjìyà? ̀yin ń pe idà sọ̀kalẹ̀ sórí gbogbo àwọn olùgbé ayé, ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ.

30 "Nísinsin yìí, sọ àsọtẹ́lẹ̀ àwọn ̀rọ̀ wọ̀nyí nípa wọn:

" o sọ , Olúwa yóò láti òkè ,

yóò kíkankíkan ilẹ̀ náà.

Yóò parí gbogbo olùgbé ayé, àwọn ń tẹ ìfúntí.

31 Ìrọ́kẹ̀kẹ̀ yóò títí òpin ilẹ̀ ayé,

nítorí Olúwa yóò ìdààmú orí

àwọn orílẹ̀-èdè náà,

yóò ìdájọ́ sórí gbogbo ènìyàn,

yóò fi àwọn olùṣe búburú fún idà,’ "

ni Olúwa .

32 Èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun ,

"ó! Ibi ń tànkálẹ̀ láti orílẹ̀-èdè kan òmíràn;

ìjì ńlá yóò ru sókè láti òpin ayé."

33 Nígbà náà, àwọn Olúwa ti pa yóò ibi gbogbo, láti ìpẹ̀kun kan òmíràn. A yóò ṣọ̀fọ̀ wọn, a yóò wọn jọ tàbí sin wọ́n; ṣùgbọ́n wọn yóò dàbí ààtàn lórí ilẹ̀.

34 , pohùnréré ẹkún ̀yin olùṣọ́-àgùntàn,

nínú eruku, ̀yin olùdarí agbo ẹran.

Nítorí ọjọ́ àti pa yín ti ,

̀yin ó ṣubú ohun èlò iyebíye.

35 Àwọn olùṣọ́-àgùntàn yóò ibi sálọ

yóò ṣí àsálà fún olórí agbo ẹran.

36 Gbọ́ igbe àwọn olùṣọ́-àgùntàn,

àti ìpohùnréré ẹkún àwọn olórí agbo ẹran;

nítorí Olúwa ń pa pápá oko tútù wọn run.

37 Ibùgbé àlàáfíà yóò di ahoro,

nítorí ìbínú ńlá Olúwa.

38 Gẹ́gẹ́ kìnnìún yóò fi ibùba rẹ̀ sílẹ̀,

ilẹ̀ wọn yóò di ahoro, nítorí idà àwọn aninilára,

àti nítorí ìbínú ńlá Olúwa.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-