Publicidade

Salmos 118

1 fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí ó dára;

àánú rẹ̀ dúró láéláé.

2 Jẹ́ Israẹli :

"Àánú rẹ̀ dúró láéláé".

3 Jẹ́ ilé Aaroni :

"Àánú rẹ̀ dúró láéláé".

4 Jẹ́ àwọn ó bẹ̀Olúwa :

"Àánú rẹ̀ dúró láéláé."

5 Nínú ìrora mi, mo sọkún Olúwa,

ó mi lóhùn nípa ó mi sílẹ̀.

6 Olúwa ń bẹ fún èmi; èmi yóò bẹ̀.

ni ènìyàn ṣe mi?

7 Olúwa ń bẹ fún mi; òun ni olùrànlọ́wọ́ mi.

Nítorí náà ni èmi ó ṣe ìṣẹ́gun mi lórí àwọn ó kórìíra mi.

8 Ó dára láti máa gbẹ́kẹ̀Olúwa

ju àti gbẹ́kẹ̀ènìyàn lọ.

9 Ó dára láti máa gbẹ́kẹ̀Olúwa

ju à ti gbẹ́kẹ̀àwọn ọmọ-aládé lọ.

10 Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè mi káàkiri,

ṣùgbọ́n orúkọ Olúwa èmi wọn kúrò.

11 Wọ́n mi káàkiri gbogbo ̀gbẹ́,

ṣùgbọ́n orúkọ Olúwa èmi wọn dànù.

12 Wọ́n gbá yìn ìn mi oyin,

ṣùgbọ́n wọ́n kíákíá iná ̀gún;

orúkọ Olúwa èmi wọn dànù.

13 Ìwọ gidigidi n ṣubú,

ṣùgbọ́n Olúwa ràn lọ́wọ́.

14 Olúwa ni agbára àti orin mi;

ó di ìgbàlà mi.

15 Ohùn ayọ̀ àti ìgbàlà ń bẹ nínú àgọ́ àwọn olódodo:

"Ọwọ́ ̀tún Olúwa ń ṣe ohun agbára!

16 Ọwọ́ ̀tún Olúwa a gbéga;

ọwọ́ ̀tún Olúwa ń ṣe ohun agbára!"

17 Èmi yóò , ṣùgbọ́n èmi yóò ,

èmi yóò pòkìkí ohun Olúwa ṣe.

18 Olúwa mi gidigidi,

ṣùgbọ́n òun fi ikú lọ́wọ́.

19 Ṣí ìlẹ̀kùn ẹnu-ọ̀òdodo fún mi:

èmi yóò ibẹ̀ wọlé, èmi yóò fi ọpẹ́ fún Olúwa.

20 Èyí ni ìlẹ̀kùn Olúwa

ibẹ̀ ni àwọn olódodo yóò wọlé.

21 Èmi yóò fi ọpẹ́ fún , nítorí ó mi lóhùn;

ìwọ di ìgbàlà mi.

22 Òkúta àwọn ̀mọ̀kọ̀sílẹ̀,

ni ó di pàtàkì igun ilé;

23 Olúwa ti ṣe èyí,

ó ṣe ìyanu ojú wa.

24 Èyí ni ọjọ́ Olúwa :

jẹ́ ayọ̀ inú wa máa dùn nínú rẹ̀.

25 Olúwa, gbà ;

Olúwa, fún wa àlàáfíà.

26 Ìbùkún ni ẹni ń bọ̀ orúkọ Olúwa.

Àwa ti fi ìbùkún fún láti ilé Olúwa .

27 Olúwa ni Ọlọ́run,

ó ti ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ tàn wa lára

pẹ̀̀ka igi ọwọ́, ó dára pọ̀ mọ́

̀pọ̀ ènìyàn ń wọ́ nínú ayọ̀

fi okùn di ẹbọ náà mọ́ ìwo pẹpẹ.

28 Ìwọ ni Ọlọ́run mi, èmi yóò máa fi ọpẹ́ fún ;

ìwọ ni Ọlọ́run mi, èmi yóò gbé ga.

29 fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí ó ṣeun;

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-