Publicidade

Salmos 31

Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi.

1 Nínú rẹ̀, Olúwa ni mo ti ààbò;

ṣe jẹ́ ojú ó ;

gbà nínú òdodo rẹ.

2 Tẹ́ etí rẹ mi,

gbà kíákíá;

jẹ́ àpáta ààbò mi,

jẹ́ odi alágbára láti gbà .

3 Ìwọ pàápàá ni àpáta àti ààbò mi,

nítorí orúkọ rẹ, máa ṣe olùtọ́ mi, o ṣe amọ̀mi.

4 Yọ jáde kúrò nínú àwọ̀n wọ́n dẹ pamọ́ fún mi,

nítorí ìwọ ni ìsádi mi.

5 ọwọ́ rẹ ni mo fi ̀mi ;

ìwọ ni o ti padà, Olúwa, Ọlọ́run òtítọ́.

6 Èmi ti kórìíra àwọn ẹni ń fiyèsí òrìṣà níye lórí;

ṣùgbọ́n èmi gbẹ́kẹ̀Olúwa.

7 Èmi yóò yọ̀, inú mi yóò dùn nínú ìfẹ́ ńlá rẹ,

nítorí ìwọ ti ìbìnújẹ́ mi

ìwọ ti mọ̀ ọkàn mi nínú ìpọ́njú.

8 Pẹ̀, ìwọ mi àwọn ̀lọ́wọ́

ìwọ ti fi ẹsẹ̀ mi ibi ààyè ńlá.

9 Ṣàánú fún mi, ìwọ Olúwa, nítorí mo nínú ìpọ́njú;

ojú mi fi ìbìnújẹ́ sùn,

ọkàn àti ara mi pẹ̀.

10 Èmi fi ìbànújẹ́ lo ọjọ́ mi

àti àwọn ọdún mi pẹ̀ìmí ̀dùn;

agbára mi ti kùnà nítorí òsì mi,

egungun mi ti rún dànù.

11 Èmi di ẹni ̀gàn láàrín àwọn ̀mi gbogbo,

pẹ̀lúpẹ̀láàrín àwọn aládùúgbò mi,

mo di ̀fún àwọn ojúlùmọ̀ mi;

àwọn ó mi òde ń yẹra fún mi.

12 Èmi ti di ẹni ìgbàgbé kúrò ọkàn gẹ́gẹ́ ẹni ó ti ;

èmi dàbí ohun èlò ó ti fọ́.

13 Nítorí mo gbọ́ ̀rọ̀ ̀gàn ̀pọ̀lọpọ̀ ìpayà ó mi ;

wọn gbìmọ̀ pọ̀ mi,

wọ́n ṣọ̀tẹ̀ mi

láti gba ̀mi.

14 Ṣùgbọ́n èmí gbẹ́kẹ̀, ìwọ Olúwa;

mo sọ , "Ìwọ Ọlọ́run mi."

15 Ìgbà mi ń bẹ ọwọ́ rẹ;

gbà kúrò ọwọ́ àwọn ̀mi

àti àwọn onínúnibíni.

16 Jẹ́ ojú rẹ ó tan ìmọ́lẹ̀ ìránṣẹ́ rẹ lára;

gbà nínú ìfẹ́ rẹ ó dúró ṣinṣin.

17 ṣe jẹ́ ojú ki ó , Olúwa;

nítorí mo ́;

jẹ́ ojú ó ti ènìyàn búburú;

jẹ́ wọ́n lọ pẹ̀ìdààmú isà òkú.

18 Jẹ́ àwọn ètè irọ́ ó dákẹ́ jẹ́́,

pẹ̀ìgbéraga àti ìkẹ́gàn,

wọ́n sọ̀rọ̀ àfojúdi olódodo.

19 Báwo ni títóbi oore rẹ̀ ti pọ̀ ,

èyí ìwọ ti ìpamọ́ fún àwọn ó bẹ̀rẹ,

èyí ìwọ rọ̀rẹ̀ níwájú àwọn ènìyàn

wọ́n fi ́ ṣe ibi ìsádi wọn.

20 abẹ́ ìbòòji iwájú rẹ ni ìwọ pa wọ́n mọ́

kúrò nínú ìdìmọ̀àwọn ènìyàn;

ibùgbé rẹ, o wọn kúrò nínú ewu

kúrò nínú ìjà ahọ́n.

21 Olùbùkún ni Olúwa,

nítorí ó ti fi àgbà ìyanu ìfẹ́ ó mi hàn,

nígbà mo ìlú wọ́n rọ̀gbà yíká.

22 Èmí ti sọ nínú ìdágìrì mi,

"A mi kúrò ojú rẹ!"

Síbẹ̀ ìwọ ti gbọ́ ̀bẹ̀ mi fún àánú

nígbà mo ́ fún ìrànlọ́wọ́.

23 fẹ́ Olúwa, gbogbo ̀yin ènìyàn rẹ̀ mímọ́!

Olúwa pa olódodo mọ́,

ó san án padà fún agbéraga ̀kúnrẹ́rẹ́.

24 Jẹ́ alágbára, yóò yín àyà le

gbogbo ̀yin ó dúró de Olúwa.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-