Publicidade

Salmos 37

Ti Dafidi.

1 ṣe ìkanra nítorí àwọn olùṣe búburú,

ìwọ ṣe ṣe ìlara nítorí àwọn oníṣẹ́ ̀ṣẹ̀;

2 nítorí wọn yóò gbẹ i koríko,

wọn yóò rẹ̀ dànù ewéko tútù.

3 Gbẹ́kẹ̀Olúwa, o máa ṣe rere;

torí ìwọ yóò gbé ilẹ̀ náà, o gbádùn ààbò rẹ̀.

4 Ṣe inú dídùn Olúwa;

òun yóò fún ìfẹ́ inú rẹ̀.

5 Fi ̀rẹ Olúwa lọ́wọ́;

gbẹ́kẹ̀pẹ̀, òun yóò ṣe é.

6 Yóò òdodo rẹ̀ jáde ìmọ́lẹ̀ òwúrọ̀,

àti ìdájọ́ rẹ̀ ̀sán gangan.

7 Ìwọ dákẹ́ jẹ́́ níwájú Olúwa,

o fi sùúrù dúró é;

ṣe ṣe ìkanra nítorí àwọn ń rere ̀wọn,

nítorí ọkùnrin náà ti èrò búburú ṣẹ.

8 Fàsẹ́yìn nínú inúbíbí, o kọ ìkáàánú sílẹ̀,

ṣe ṣe ìkanra, ó ba à ṣé búburú pẹ̀.

9 Nítorí á ó àwọn olùṣe búburú kúrò,

ṣùgbọ́n àwọn ó dúró de Olúwa àwọn ni yóò jogún ilẹ̀ náà.

10 Síbẹ̀ nígbà díẹ̀ i, àwọn ènìyàn búburú yóò mọ̀;

nítòótọ́ ìwọ yóò fi ara balẹ̀ wo ipò rẹ̀, wọn yóò níbẹ̀.

11 Ṣùgbọ́n àwọn ọlọ́kàn tútù ni yóò jogún ilẹ̀ náà,

wọn yóò máa ṣe inú dídùn nínú ̀pọ̀lọpọ̀ àlàáfíà.

12 Ènìyàn búburú di rìkíṣí olóòtítọ́,

wọ́n pa eyín wọn keke wọn;

13 ṣùgbọ́n Olúwa rẹ́rìn-ín àwọn ènìyàn búburú,

nítorí ó ọjọ́ wọn ń bọ̀.

14 Ènìyàn búburú fa idà yọ,

wọ́n tẹ àwọn ọrun wọn,

láti sọ tálákà àti aláìní kalẹ̀,

láti pa àwọn ó dúró ṣinṣin.

15 Idà wọn yóò wọ àyà wọn lọ,

àti ọrun wọn yóò ṣẹ́.

16 Ohun díẹ̀ olódodo ,

sàn ju ̀pọ̀ ọrọ̀ ènìyàn búburú;

17 nítorí a óò ṣẹ́ ọwọ́ àwọn ènìyàn búburú,

ṣùgbọ́n Olúwa gbé olódodo sókè.

18 Olúwa mọ àwọn ọjọ́ àwọn dúró ṣinṣin,

àti ilẹ̀ ìní wọn yóò títí ayérayé.

19 Ojú yóò wọ́n àkókò ibi,

àti ọjọ́ ìyàn, a ó tẹ́ wọn lọ́rùn.

20 Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn búburú yóò ṣègbé.

Àwọn ̀Olúwa yóò dàbí ẹwà oko tútù;

wọn lọ; bi èéfín ni wọn yóò lọ kúrò.

21 Àwọn ènìyàn búburú , wọn san án padà,

ṣùgbọ́n àwọn olódodo a máa ṣàánú, a máa fi fún ni;

22 nítorí àwọn Olúwa bùkún ni yóò jogún ilẹ̀ náà,

àwọn ó fi ni a ó kúrò.

23 Ìlànà ìgbésẹ̀ ènìyàn rere láti ̀dọ̀ Olúwa ,

o ṣe inú dídùn ̀rẹ̀;

24 ó tilẹ̀ ṣubú a yóò ta á pátápátá,

nítorí Olúwa di ọwọ́ rẹ̀ .

25 Èmi ti ni èwe, báyìí èmi dàgbà;

síbẹ̀ èmi ì ì ri a kọ olódodo sílẹ̀,

tàbí irú-ọmọ rẹ̀ máa ṣagbe oúnjẹ.

26 Aláàánú ni òun nígbà gbogbo a máa ni;

a máa bùsi i fún ni.

27 Lọ kúrò nínú ibi, o máa ṣe rere;

nígbà náà ni ìwọ yóò gbé ilẹ̀ náà títí láéláé.

28 Nítorí Olúwa fẹ́ràn ìdájọ́ òtítọ́,

kọ àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀ sílẹ̀.

Àwọn olódodo ni a ó pamọ́ títí ayérayé,

ṣùgbọ́n àwọn ọmọ ènìyàn búburú ni a ó kúrò.

29 Olódodo ni yóò jogún ilẹ̀ náà,

yóò máa gbé ibẹ̀ títí ayérayé.

30 Ẹnu olódodo sọ̀rọ̀ ọgbọ́n,

ahọ́n rẹ̀ a máa sọ̀rọ̀ ìdájọ́.

31 Òfin Ọlọ́run rẹ̀ ń bẹ àyà wọn;

àwọn ìgbésẹ̀ rẹ̀ yóò yẹ̀.

32 Ènìyàn búburú ń ṣọ́ olódodo,

Ó ń ̀láti pa á.

33 Olúwa yóò fi e lọ́wọ́ yóò a lẹ́bi,

nígbà a ń ṣe ìdájọ́ rẹ̀.

34 Dúró de Olúwa,

o máa pa ̀rẹ̀ mọ́.

Yóò gbé lékè láti jogún ilẹ̀ náà;

nígbà a àwọn ènìyàn búburú kúrò ìwọ yóò ri.

35 Èmi ti ènìyàn búburú ń hu ìwà ìkà,

ó fi ara rẹ̀ gbilẹ̀ igi tútù ńlá,

36 ṣùgbọ́n ìṣẹ́kan i ó kọjá lọ, kíyèsi, mọ́;

bi ó tilẹ̀ jẹ́ mo a kiri, ṣùgbọ́n a le è ri.

37 Máa kíyèsi ẹni pípé, o wo ẹni dúró ṣinṣin;

nítorí àlàáfíà ni òpin ọkùnrin náà.

38 Ṣùgbọ́n àwọn olùrékọjá ni a ó parun papọ̀;

ìran àwọn ènìyàn búburú ni a ó kúrò.

39 Ìgbàlà àwọn onídùúró ṣinṣin láti ̀dọ̀ Olúwa;

òun ni ààbò wọn ìgbà ìpọ́njú

40 Olúwa yóò ràn wọ́n lọ́wọ́ yóò gbà wọ́n;

yóò gbà wọ́n lọ́wọ́ ènìyàn búburú, yóò gbà wọ́n ,

nítorí wọ́n gbẹ́kẹ̀e.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-