Publicidade

Salmos 38

Saamu Dafidi. ̀bẹ̀.

1 Olúwa, ṣe mi nínú ìbínú rẹ,

bẹ́̀ ni o ṣe fi ìyà jẹ nínú ìrunú rẹ̀.

2 Nítorí ọfà rẹ kàn mọ́ mi ṣinṣin,

ọwọ́ rẹ mọ́lẹ̀.

3 ibi yíyè ara à mi, nítorí ìbínú rẹ;

àlàáfíà nínú egungun mi nítorí i ̀ṣẹ̀ mi.

4 Nítorí àìṣedéédéé mi ti borí mi mọ́lẹ̀;

wọ́n ìwọ̀n bi àjàgà ó wúwo fún mi.

5 Ọgbẹ́ mi ń rùn ó díbàjẹ́

nítorí òmùgọ̀ mi.

6 Èmi ń jòwèrè, orí mi tẹ̀ ba gidigidi

èmi ń ṣọ̀fọ̀ rìn kiri gbogbo ọjọ́.

7 Nítorí ̀gbẹ́ mi kún fún ìgbóná ń jóni

ṣí ibi yíyè ara mi.

8 Ara mi , a mi jẹ́gẹjẹ̀gẹ;

mo kérora nítorí ìrúkèrúdò àyà mi.

9 Olúwa, gbogbo ìfẹ́ mi ń bẹ níwájú rẹ;

ìmí ̀dùn mi pamọ́ fún .

10 Àyà mi ń hẹlẹ, agbára mi yẹ̀ sílẹ̀;

ó ṣe ti ìmọ́lẹ̀ ojú mi ni, ó ti lọ kúrò lára mi.

11 Àwọn ̀rẹ́ mi àti àwọn ẹlẹgbẹ́ mi dúró lókèèrè réré kúrò níbi ìpọ́njú mi,

àwọn alábágbé mi, dúró lókèèrè.

12 Àwọn n ̀mi dẹ okùn sílẹ̀ fún mi;

àti àwọn ó fẹ́ pa lára ń sọ̀rọ̀ nípa ìparun,

wọ́n ń gbèrò ̀tàn gbogbo ọjọ́.

13 Ṣùgbọ́n mo dàbí adití odi, èmi gbọ́ ̀rọ̀;

àti odi, le sọ̀rọ̀.

14 Nítòótọ́, mo ọkùnrin gbọ́rọ̀,

àti ẹnu ẹni ìjiyàn.

15 Ṣùgbọ́n Olúwa, ìwọ ni mo dúró ;

ìwọ ni, Olúwa Ọlọ́run mi, ẹni yóò dáhùn.

16 Nítorí mo gbàdúrà, "Gbóhùn mi, wọn ba à yọ̀ ;

nígbà ẹsẹ̀ mi yọ̀ wọn yóò máa gbé ara wọn ga mi."

17 Nítorí mo ti ṣetán láti ṣubú,

ìrora mi pẹ̀mi nígbà gbogbo.

18 Mo jẹ́wọ́ ìrékọjá mi;

àánú ṣe fún ̀ṣẹ̀ mi.

19 Àwọn ó jẹ́ ̀mi láìnídìí pàtàkì, wọ́n lágbára púpọ̀,

̀pọ̀lọpọ̀ ni àwọn ó kórìíra mi lọ́òdì.

20 Àwọn wọn ń fi ibi san rere fún mi

àwọn ni ̀mi

nítorí ń tọ ìre lẹ́yìn.

21 ṣe kọ̀ sílẹ̀, ìwọ Olúwa!

Ọlọ́run mi, ṣe jìnnà mi.

22 Yára láti ràn lọ́wọ́,

Olúwa, Olùgbàlà mi.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-