Publicidade

Salmos 51

Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi. Nígbà ti wòlíì Natani tọ , lẹ́yìn Dafidi ̀ṣẹ̀ àgbèrè rẹ̀ pẹ̀Batṣeba.

1 Ṣàánú fún mi, Ọlọ́run,

gẹ́gẹ́ ìdúró ṣinṣin ìfẹ́ rẹ̀,

gẹ́gẹ́ ̀pọ̀ àánú rẹ̀

o pa gbogbo ̀ṣẹ̀ mi rẹ́.

2 Wẹ gbogbo àìṣedéédéé mi kúrò

o wẹ̀ mi mọ́ kúrò nínú ̀ṣẹ̀ mi!

3 Nítorí mo mọ̀ gbogbo ̀ṣẹ̀ mi,

nígbà gbogbo ni ̀ṣẹ̀ mi níwájú mi.

4 , ìwọ nìkan ṣoṣo, ni mo dẹ́ṣẹ̀

ni mo ṣe búburú níwájú rẹ̀,

a láre nígbà ìwọ ń sọ̀rọ̀,

o le láìlẹ́bi, nígbà ìwọ ń ṣe ìdájọ́.

5 Nítòótọ́, nínú ̀ṣẹ̀ ni a ti mi,

nínú ̀ṣẹ̀ ni ìyá lóyún mi.

6 Nítòótọ́ ìwọ fẹ́ òtítọ́ inú;

ìwọ kọ́ mi ọgbọ́n ìhà ìkọ̀kọ̀.

7 Wẹ̀ pẹ̀ewé hísópù, èmi yóò mọ́;

fọ̀ , èmi yóò funfun ju yìnyín lọ.

8 Jẹ́ n gbọ́ ayọ̀ àti inú dídùn;

jẹ́ gbogbo egungun ìwọ ti run ó máa yọ̀.

9 Pa ojú rẹ̀ mọ́ kúrò nínú ̀ṣẹ̀ mi

o pa gbogbo àwọn àìṣedéédéé mi rẹ́.

10 ọkàn mímọ́ inú mi, Ọlọ́run,

o tún ̀dídúró ṣinṣin ṣe sínú mi.

11 ṣe mi kúrò níwájú rẹ,

o ṣe gba ̀Mímọ́ rẹ lọ́wọ́ mi.

12 ayọ̀ ìgbàlà rẹ tọ̀ ,

o fún mi ̀ìfẹ́, yóò mi dúró.

13 Nígbà náà ni èmi yóò máa kọ́ àwọn olùrékọjá ̀rẹ,

àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ yóò padà .

14 Gbà kúrò lọ́wọ́ ̀bi ̀jẹ̀, Ọlọ́run,

ìwọ Ọlọ́run ìgbàlà mi,

ahọ́n mi yóò máa kọrin òdodo rẹ kíkan.

15 Olúwa, ṣí mi ètè mi gbogbo,

àti ẹnu mi yóò máa kéde ìyìn rẹ.

16 Nítorí ìwọ inú dídùn ẹbọ, èmi ;

Ìwọ inú dídùn ọrẹ ẹbọ sísun.

17 Ẹbọ Ọlọ́run ni ìròbìnújẹ́ ọkàn ìròbìnújẹ́ àti ìrora àyà.

18 Ṣe rere dídùn inú rẹ Sioni,

ṣe rere; tún odi Jerusalẹmu mọ.

19 Nígbà náà ni inú rẹ yóò dùn ẹbọ òdodo,

pẹ̀ọrẹ ẹbọ sísun àti ̀tọ̀̀tọ̀ ọrẹ ẹbọ sísun,

nígbà náà ni wọn yóò fi akọ màlúù ẹbọ lórí pẹpẹ rẹ.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-