Pular para o conteúdo
Publicidade

Salmos 56

Fún adarí orin. Ti ohùn "Àdàbà lórí Óákù òkè réré." Ti Dafidi. Miktamu. Nígbà àwọn ará Filistini ka mọ́ Gati.

1 Ṣàánú fún mi, Ọlọ́run,

nítorí àwọn ènìyàn ń fi ìgbónára lépa mi;

gbogbo ọjọ́ ni wọn ń kọjú ìjà mi, wọn ń ni mi lára.

2 Àwọn ̀mi ń mi gbogbo ọjọ́,

àwọn ènìyàn ń kọjú ìjà mi nínú ìgbéraga wọn.

3 Nígbà ̀ń ,

èmi o gbẹ́kẹ̀.

4 Nínú Ọlọ́run èmi yóò máa yìn ̀rọ̀ rẹ,

nínú Ọlọ́run ni ìgbẹ́kẹ̀mi; ̀yóò

ni ẹran-ara ṣe mi?

5 Wọn ń ̀rọ̀ gbogbo ọjọ́,

wọn ń gbèrò nígbà gbogbo láti ṣe níbi.

6 Wọn ara wọn jọ, wọ́n ba.

Wọ́n ń ṣọ́ ìgbésẹ̀ mi

wọn ń làkàkà láti gba ̀mi.

7 San ̀san iṣẹ́ búburú wọ́n fún wọn;

ìbínú rẹ, Ọlọ́run, wọ́ àwọn ènìyàn náà bọ́ sílẹ̀.

8 Kọ ẹkún mi sílẹ̀;

omijé mi ìgò rẹ,

wọ́n ha nínú ìkọ̀sílẹ̀ rẹ ?

9 Nígbà náà ni àwọn ̀mi yóò pẹ̀yìndà

nígbà mo fún ìrànlọ́wọ́

nípa èyí ni mo mọ̀ Ọlọ́run ń bẹ fún mi.

10 Nínú Ọlọ́run, ẹni mo yìn ̀rọ̀ rẹ̀

nínú Olúwa, ẹni mo yin ̀rọ̀ rẹ̀,

11 nínú Ọlọ́run ni ìgbẹ́kẹ̀mi:

̀yóò .

ni ènìyàn ṣe mi?

12 Mo jẹ́ ̀jẹ́ lábẹ́ rẹ Ọlọ́run:

èmi o ìyìn mi fún .

13 Nítorí ìwọ gbà lọ́wọ́ ikú

àti ẹsẹ̀ mi lọ́wọ́ ìṣubú,

èmí máa rìn níwájú Ọlọ́run

ìmọ́lẹ̀ àwọn alààyè.

Veja também