Publicidade

Salmos 77

Fún adarí orin. Fún Jedutuni. Ti Asafu. Saamu.

1 kígbe Ọlọ́run fún ìrànlọ́wọ́;

mo kígbe Ọlọ́run láti gbọ́ tèmi.

2 Nígbà mo nínú ìpọ́njú,

mo Olúwa;

òru ni mo na ọwọ́ mi jáde àìkáárẹ̀

ọkàn kọ̀ láti ú nínú.

3 Èmi rántí rẹ, Ọlọ́run,

mo kẹ́dùn;

mo ṣe àròyé, ̀mi rẹ̀wẹ̀. Sela.

4 Ìwọ fẹ́ èmi fi ojú ba oorun,

mo dààmú bẹ́̀ ń le sọ̀rọ̀.

5 Mo ronú nípa ọjọ́ ìgbàanì;

ọdún pípẹ́ sẹ́yìn;

6 mo rántí orin mi òru.

Èmi ń àyà mi sọ̀rọ̀,

ọkàn mi ń ṣe àwárí jọjọ.

7 "Olúwa yóò ha kọ̀ títí láé?

Ki yóò ha ṣe ojúrere rẹ̀ mọ́?

8 Ṣe ìfẹ́ rẹ̀ àti àánú rẹ̀ ti lọ láéláé?

Ìlérí rẹ̀ ha kùnà títí ayé?

9 Ọlọ́run ha gbàgbé láti máa ṣàánú?

ìbínú rẹ̀, ó ha ojúrere rẹ̀ mọ́?" Sela.

10 Èmi , "Èyí ̀dùn ọkàn mi,

ọwọ́ ̀tún ̀gá-ògo jùlọ ti yípadà".

11 Èmi ó rántí iṣẹ́ Olúwa:

bẹ́̀ ni, èmi ó rántí iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ ọjọ́ pípẹ́.

12 Èmi ṣàṣàrò lórí iṣẹ́ rẹ gbogbo,

pẹ̀, ènìyàn máa sọ̀rọ̀ gbogbo iṣẹ́ agbára rẹ.

13 Ọlọ́run, ̀rẹ jẹ́ mímọ́.

Ọlọ́run wo ni ó tóbi Ọlọ́run wa?

14 Ìwọ ni Ọlọ́run ń ṣe ìyanu;

ìwọ fi agbára rẹ hàn nínú àwọn ènìyàn.

15 Pẹ̀ọwọ́ agbára rẹ ni ìwọ ra àwọn ènìyàn padà,

àwọn ọmọ Jakọbu àti Josẹfu. Sela.

16 Nígbà àwọn omi Ọlọ́run,

nígbà àwọn omi ,

̀wọ́n,

nítòótọ́ ara ibú balẹ̀.

17 Àwọn ojú ̀run omi sílẹ̀,

àwọsánmọ̀ fi àrá dáhùn;

ọfà rẹ̀ ń tàn sẹ́yìn àti síwájú.

18 Àrá rẹ̀ ni a gbọ́ nínú ìjì,

ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ mọ́lẹ̀ gbogbo ayé;

ayé bẹ̀, wọ́n wárìrì.

19 Ipa rẹ̀ gba Òkun, ̀rẹ̀ ń bẹ nínú Òkun,

̀la omi alágbára kọjá ipa rẹ̀ ń bẹ nínú líla omi alágbára kọjá,

nítòótọ́ a ojú ẹsẹ̀ rẹ̀.

20 Ó tọ́ àwọn ènìyàn rẹ̀ gẹ́gẹ́ ̀wọ́ ẹran

nípa ọwọ́ Mose àti Aaroni.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-