Publicidade

Salmos 84

Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ ti gittiti. Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu.

1 Ibùgbé rẹ̀ ti lẹ́,

Olúwa àwọn ọmọ-ogun!

2 Ọkàn mi ń ṣàfẹ́nítòótọ́

ó tilẹ̀ pòǹgbẹ fún àgbàlá Olúwa

àyà mi àti ara mi ń kọrin ayọ̀

Ọlọ́run alààyè.

3 Nítòótọ́ ológoṣẹ́ ri ilé,

ẹyẹ alápáǹdẹ̀dẹ̀ tẹ́ ìtẹ́ fún ara rẹ̀,

níbi yóò máa pa ọmọ rẹ̀ mọ́ :

ibùgbé tòsí pẹpẹ rẹ̀,

Olúwa àwọn ọmọ-ogun, ọba àti Ọlọ́run mi.

4 Ìbùkún fún àwọn ó ń gbé inú ilé rẹ;

wọn ó máa yìn ́ títí láé.

5 Ìbùkún ni fún àwọn agbára wọn nínú rẹ

àwọn wọ́n gbé ọkàn bíbẹ ibi mímọ́ .

6 Àwọn ń la àfonífojì omijé lọ

wọn sọ ́ di kànga

àkọ́rọ̀ òjò fi ìbùkún ó.

7 Wọ́n ń lọ láti ipa ipá

títí ̀kọ̀̀kan fi farahàn níwájú Ọlọ́run Sioni.

8 Gbọ́ àdúrà mi, Olúwa Ọlọ́run Alágbára;

tẹ́mi, Ọlọ́run Jakọbu.

9 Wo asà wa, Ọlọ́run;

fi ojú àánú àwọn ẹni àmì òróró rẹ.

10 Dídára ọjọ́ kan ààfin rẹ

ju ẹgbẹ̀rún (1,000) ọjọ́ lọ;

èmi o kúkú máa ṣe aṣọ́nínú ilé Ọlọ́run mi

láti gbé àgọ́ àwọn ènìyàn búburú.

11 Nítorí Olúwa Ọlọ́run jẹ́ òòrùn àti asà;

Olúwa fún ni ojúrere àti ọlá;

ohun rere kan yóò fàsẹ́yìn

fún àwọn ó rìn àìlábùkù.

12 Olúwa àwọn ọmọ-ogun,

ìbùkún ni fún ọkùnrin náà ó gbẹ́kẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-