Publicidade

Salmos 91

1 Ẹni ó gbé ibi ìkọ̀kọ̀ ̀gá-ògo

ni yóò sinmi ibi òjìji Olódùmarè.

2 Èmi yóò sọ nípa ti Olúwa ,

"Òun ni ààbò àti odi mi,

Ọlọ́run mi, ẹni èmi gbẹ́kẹ̀".

3 Nítòótọ́ òun yóò gbà nínú

ìdẹ̀kùn àwọn pẹyẹpẹyẹ

àti nínú àjàkálẹ̀-ààrùn búburú.

4 Òun yóò fi ìyẹ́ rẹ̀ ,

àti ni abẹ́ ìyẹ́ rẹ̀ ni èmi yóò ti ààbò;

òtítọ́ rẹ̀ ni yóò ṣe ààbò àti odi mi.

5 Ìwọ yóò bẹ̀nítorí ̀òru,

tàbí fún ọfà ń ̀sán,

6 tàbí fún àjàkálẹ̀-ààrùn ń rìn kiri òkùnkùn,

tàbí fún ìparun ń rìn kiri ̀sán gangan.

7 Ẹgbẹ̀rún (1,000) yóò ṣubú ̀gbẹ́ rẹ,

ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (10,000) ọwọ́ ̀tún rẹ,

ṣùgbọ́n yóò súnmọ́ ̀dọ̀ rẹ.

8 Ìwọ yóò máa ó pẹ̀ojú rẹ

àti wo ìjìyà àwọn ẹni búburú.

9 Nítorí ìwọ fi Olúwa ṣe ààbò rẹ,

ìwọ fi ̀gá-ògo ṣe ibùgbé rẹ.

10 Búburú kan ki yóò ṣubú ́,

Bẹ́̀ ni ààrùnkárùn yóò súnmọ́ ilé rẹ.

11 Nítorí yóò fi àṣẹ fún àwọn angẹli nípa tìrẹ

láti pa ́ mọ́ gbogbo ̀rẹ;

12 wọn yóò gbé sókè ọwọ́ wọn,

nítorí ìwọ ba à fi ẹsẹ̀ rẹ gún òkúta.

13 Ìwọ yóò rìn lórí kìnnìún àti paramọ́lẹ̀;

ìwọ yóò tẹ kìnnìún ńlá àti ejò ńlá ni ìwọ yóò fi ẹsẹ̀ tẹ̀ mọ́lẹ̀.

14 "Nítorí ti ìfẹ́ rẹ mi, èmi yóò gbà ́;

èmi yóò pa ́ mọ́, nítorí ìwọ jẹ́wọ́ orúkọ mi.

15 Òun yóò , èmi yóò a lóhùn;

èmi yóò pẹ̀rẹ̀ nínú ìpọ́njú,

èmi yóò gbà á, èmi yóò bu ọlá fún un.

16 Pẹ̀̀gígùn ni èmi yóò fi tẹ́ lọ́rùn,

èmi yóò fi ìgbàlà mi hàn án."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-