Publicidade

Salmos 102

Àdúrà olùpọ́njú àárẹ̀ , ó ọkàn rẹ̀ payá níwájú Olúwa.

1 Gbọ́ àdúrà mi, Olúwa,

jẹ́ igbe ̀bẹ̀ mi ó ̀dọ̀ rẹ.

2 ṣe pa ojú rẹ mọ́ kúrò lọ́dọ̀ mi

ọjọ́ èmi nínú ìpọ́njú.

Dẹ etí rẹ mi;

nígbà mo , mi lóhùn kíákíá.

3 Nítorí ọjọ́ mi run èéfín;

egungun mi jóná ààrò.

4 Àyà mi , ó rọ i koríko;

mo gbàgbé láti jẹ oúnjẹ mi.

5 Nítorí ohùn ìkérora mi,

egungun mi lẹ̀ mọ́ ẹran-ara mi.

6 Èmi dàbí ẹyẹ igún ijù:

èmi dàbí òwìwí ibi ahoro.

7 Èmi dìde; èmi dàbí ẹyẹ lórí ilé.

8 ọjọ́ gbogbo, àwọn ̀ológoṣẹ́ mi ń gàn ;

àwọn ń ṣe ìkanra mi ń fi orúkọ mi .

9 Èmi jẹ eérú gẹ́gẹ́ oúnjẹ mi, èmi da ohun mímu mi pọ̀ pẹ̀omijé.

10 Nítorí ìbínú ríru rẹ, nítorí ìwọ ti gbé mi sókè, ìwọ gbé mi ṣánlẹ̀.

11 Ọjọ́ mi dàbí òjìji àṣálẹ́

èmi rọ koríko.

12 Ṣùgbọ́n ìwọ, Olúwa, ni yóò dúró láéláé;

ìrántí rẹ láti ìran ìran.

13 Ìwọ ó dìde ìwọ ó ṣàánú fún Sioni,

nítorí ìgbà àti ṣe ojúrere i;

àkókò náà ti .

14 Nítorí àwọn òkúta jẹ́ inú dídùn àwọn ìránṣẹ́ rẹ;

wọ́n káàánú erùpẹ̀ rẹ.

15 Àwọn kèfèrí yóò bẹ̀orúkọ Olúwa,

gbogbo ọba ayé yóò máa bẹ̀ògo rẹ.

16 Torí Olúwa yóò gbé Sioni , yóò farahàn nínú ògo rẹ̀.

17 Yóò dáhùn àdúrà àwọn aláìní;

yóò gan ̀bẹ̀ wọn.

18 Jẹ́ a kọ èyí fún ìran ń bọ̀,

àwọn ènìyàn a ì yóò yin Olúwa:

19 "Olúwa wo ilẹ̀ láti òkè mímọ́ rẹ̀

láti ̀run ni ó bojú wo ayé,

20 láti gbọ́ ìrora ará túbú,

láti àwọn a yàn ikú sílẹ̀."

21 a sọ orúkọ Olúwa Sioni

àti ìyìn rẹ̀ Jerusalẹmu.

22 ìgbà a àwọn ènìyàn àti

ìjọba pọ̀ láti máa sìn Olúwa.

23 ipa ̀mi, ó rẹ agbára mi sílẹ̀,

ó ọjọ́ mi kúrú.

24 Èmi :

"Ọlọ́run mi, ṣe mi kúrò agbede-méjì ọjọ́ mi; ọdún rẹ̀ ń lọ láti ìran ìran.

25 ìbẹ̀rẹ̀ ìwọ fi ìpìlẹ̀ ayé sọlẹ̀,

̀run jẹ́ iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.

26 Wọn yóò ṣègbé, wọn yóò parun, ṣùgbọ́n ìwọ yóò ;

gbogbo wọn ni yóò gbó aṣọ.

̀ni ìwọ yóò pààrọ̀ wọn

wọn yóò di àpatì.

27 Ṣùgbọ́n ìwọ digbí síbẹ̀,

ọdún rẹ òpin.

28 Àwọn ọmọ ìránṣẹ́ rẹ̀ yóò dúró iwájú rẹ pẹ́;

a ó fi ẹsẹ̀ irú-ọmọ wọn sọlẹ̀ iwájú rẹ."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-