Publicidade

Salmos 105

1 105.1-15: 1Ki 16.8-22. fi ọpẹ́ fún Olúwa, pe orúkọ rẹ̀,

jẹ́ a mọ ohun ó ṣe láàrín àwọn orílẹ̀-èdè.

2 Kọrin i, kọrin ìyìn i;

sọ ti iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ gbogbo.

3 Ṣògo nínú orúkọ mímọ́ rẹ̀,

jẹ́ ọkàn àwọn ń Olúwa ó yọ̀.

4 Olúwa àti ipá rẹ̀;

wa ojú rẹ̀ nígbà gbogbo.

5 Rántí àwọn ìyanu ó ti ṣe,

ìyanu rẹ̀, àti ìdájọ́ ó sọ,

6 ̀yin ìran Abrahamu ìránṣẹ́ rẹ̀,

̀yin ọmọkùnrin Jakọbu, àyànfẹ́ rẹ̀.

7 Òun ni Olúwa Ọlọ́run wa:

ìdájọ́ rẹ̀ gbogbo ayé.

8 105.8-9: Lk 1.72-73. Ó rántí májẹ̀rẹ̀ láéláé,

̀rọ̀ ó pàṣẹ, fún ẹgbẹẹgbẹ̀rún ìran,

9 májẹ̀ó pẹ̀Abrahamu,

ìbúra ó ṣe pẹ̀fún Isaaki.

10 Ó ṣe ìdánilójú u rẹ̀ fún Jakọbu gẹ́gẹ́ àṣẹ,

Israẹli, gẹ́gẹ́ bi májẹ̀ayérayé:

11 "Fún ìwọ ni èmi ó fún ilẹ̀ Kenaani

gẹ́gẹ́ ìpín ìwọ ó jogún."

12 Nígbà wọn kéré níye,

wọ́n kéré jọjọ, àti àwọn àjèjì níbẹ̀

13 wọ́n rìn kiri láti orílẹ̀-èdè orílẹ̀-èdè,

láti ìjọba kan èkejì.

14 gba ẹnikẹ́ni láààyè láti pọ́n wọn lójú;

ó fi ọba nítorí tiwọn:

15 "ṣe fọwọ́ kan ẹni àmì òróró mi; ṣe wòlíì mi níbi."

16 Ó pe ìyàn sórí ilẹ̀ náà

ó pa gbogbo ìpèsè oúnjẹ wọn run;

17 Ó rán ọkùnrin kan síwájú wọn

Josẹfu a gẹ́gẹ́ ẹrú.

18 Wọn fi ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ bọ ẹsẹ̀ rẹ̀

a gbé ọrùn rẹ̀ sínú irin,

19 títí ̀rọ̀ ó sọtẹ́lẹ̀ fi ṣẹ

títí ̀rọ̀ Olúwa fi a láre.

20 Ọba ránṣẹ́ lọ u sílẹ̀

àwọn aláṣẹ ènìyàn u sílẹ̀

21 Ó fi jẹ olúwa lórí ilẹ̀ rẹ̀,

aláṣẹ lórí ohun gbogbo ó ,

22 gẹ́gẹ́ ìfẹ́ rẹ̀, ó máa

ṣe àkóso àwọn ọmọ-aládé

ó kọ́ àwọn àgbàgbà rẹ̀ ọgbọ́n.

23 Israẹli Ejibiti;

Jakọbu ṣe àtìpó ilé Hamu.

24 Olúwa, àwọn ọmọ rẹ̀ i

ó wọn lágbára

àwọn ̀wọn lọ

25 Ó wọn lọ́kàn padà láti kórìíra àwọn ènìyàn

láti ṣe àrékérekè àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀.

26 Ó rán Mose ìránṣẹ́ rẹ̀,

àti Aaroni ó ti yàn.

27 Wọ́n ń ṣe iṣẹ́ ìyanu láàrín wọn

ó ṣe iṣẹ́ ìyanu Hamu.

28 Ó rán òkùnkùn, o ilẹ̀ ṣú

wọn sọ̀rọ̀-òdì ̀rọ̀ rẹ̀.

29 Ó sọ omi wọn di ̀jẹ̀,

ó pa ẹja wọn.

30 Ilẹ̀ ̀pọ̀lọ́ jáde ,

èyí ó lọ ìyẹ̀àwọn ọba wọn.

31 Ó sọ̀rọ̀, onírúurú eṣinṣin dìde,

ó hu kantíkantí ilẹ̀ wọn

32 Ó sọ òjò di yìnyín,

àti ̀wọ́-iná ilẹ̀ wọn;

33 Ó lu àjàrà wọn àti igi ̀pọ̀tọ́ wọn

ó igi orílẹ̀-èdè wọn.

34 Ó sọ̀rọ̀, eṣú ,

àti kòkòrò àìníye,

35 wọn jẹ gbogbo ewé ilẹ̀ wọn,

wọ́n jẹ èso ilẹ̀ wọn run.

36 Nígbà náà, ó kọlu gbogbo àwọn ilẹ̀ wọn,

ààyò gbogbo ipá wọn.

37 Ó Israẹli jáde

ti òun ti fàdákà àti wúrà,

nínú ̀rẹ̀ aláìlera kan.

38 Inú Ejibiti dùn nígbà wọn ń lọ,

nítorí ̀àwọn Israẹli ń wọ́n.

39 Ó ta àwọsánmọ̀ fún ìbòrí,

àti iná láti fún wọn ìmọ́lẹ̀ lálẹ́.

40 Wọn béèrè, ó ẹyẹ àparò ,

ó fi oúnjẹ ̀run tẹ́ wọn lọ́rùn.

41 Ó la àpáta, ó omi jáde;

gẹ́gẹ́ odò ń sàn níbi gbígbẹ.

42 Nítorí ó rántí ìlérí mímọ́ rẹ̀

àti Abrahamu ìránṣẹ́ rẹ̀.

43 Ó fi ayọ̀ àwọn ènìyàn rẹ̀ jáde

pẹ̀ayọ̀ ó yan àyànfẹ́ rẹ̀

44 Ó fún wọn ilẹ̀ ìní náà,

wọ́n jogún iṣẹ́ àwọn ènìyàn náà,

45 wọn ó máa pa àṣẹ rẹ̀ mọ́

wọn ó kíyèsi òfin rẹ̀.

fi ìyìn fún Olúwa.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-