Publicidade

Salmos 108

Orin. Saamu ti Dafidi.

1 108.1-5: Sm 57.7-11. Ọlọ́run, ọkàn mi dúró ṣinṣin

èmi ó máa kọrin, èmi ó máa fi ọkàn mi kọrin.

2 ohun èlò orin àti haapu!

Èmi ó kùtùkùtù,

3 èmi ó yìn ́, Olúwa, nínú àwọn orílẹ̀-èdè,

èmi ó kọrin rẹ nínú àwọn ènìyàn.

4 Nítorí o tóbi àánú rẹ

ju àwọn ̀run lọ

àti òdodo rẹ àwọsánmọ̀.

5 Gbé ara rẹ ga, Ọlọ́run, lórí àwọn ̀run,

àti ògo rẹ lórí gbogbo ayé.

6 108.6-13: Sm 60.5-12. a gba àwọn olùfẹ́ rẹ ;

fi ọwọ́ ̀tún rẹ ṣe ìgbàlà,

o mi lóhùn

7 Ọlọ́run ti sọ̀rọ̀ láti ibi mímọ́ rẹ̀ ,

"Èmi yóò yọ̀, èmi yóò pín Ṣekemu,

èmi yóò wọn àfonífojì Sukkoti kúrò.

8 Gileadi ni tèmi, Manase ni tèmi,

Efraimu ni ìbòrí mi,

Juda ni olófin mi,

9 Moabu ni ìkòkò ìwẹsẹ̀ mi,

lórí Edomu ni èmi ó bọ́ bàtà mi ,

lórí òkè Filistia ni èmi yóò ìhó ayọ̀."

10 Ta ni yóò mi ìlú olódi?

Ta ni yóò sìn Edomu?

11 Ìwọ Ọlọ́run ha kọ́, ìwọ ó ti kọ̀ sílẹ̀.

Ọlọ́run ìwọ yóò àwọn jagunjagun wa jáde mọ́.

12 Fún wa ìrànlọ́wọ́ nínú ìpọ́njú,

nítorí ìrànlọ́wọ́ ènìyàn asán ni.

13 Nípasẹ̀ Ọlọ́run ni àwa ó ṣe akin

nítorí òun ó tẹ àwọn ̀wa mọ́lẹ̀.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_15-35-42-