Publicidade

Salmos 128

Orin fún ìgòkè.

1 Ìbùkún ni fún gbogbo ẹni ó bẹ̀Olúwa:

ó ń rìn ̀rẹ̀.

2 Nítorí ìwọ yóò jẹ iṣẹ́ ọwọ́ rẹ

ìbùkún ni fún ; yóò dára fún .

3 Obìnrin rẹ yóò dàbí àjàrà rere

eléso púpọ̀ àárín ilé rẹ;

àwọn ọmọ rẹ yóò dàbí igi olifi ó tábìlì rẹ .

4 Kíyèsi i , bẹ́̀ ni a ó bùsi i fún ọkùnrin náà,

ó bẹ̀Olúwa.

5 Olúwa ó bùsi i fún láti Sioni ,

ìwọ ó máa ìre

Jerusalẹmu ọjọ́ ayé rẹ gbogbo.

6 Bẹ́̀ ni ìwọ ó máa àti ọmọdọ́mọ rẹ.

Láti àlàáfíà lára Israẹli.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-