Pular para o conteúdo
Publicidade

Salmos 135

1 yin Olúwa.

yin orúkọ Olúwa;

yìn ín, ̀yin ìránṣẹ́ Olúwa.

2 ̀yin ń dúró ilé Olúwa,

nínú àgbàlá ilé Ọlọ́run wa.

3 yin Olúwa: nítorí Olúwa ṣeun;

kọrin ìyìn orúkọ rẹ̀; nítorí ó dùn.

4 Nítorí Olúwa ti yan Jakọbu fún ara rẹ̀;

àní Israẹli fún ìṣúra ààyò rẹ̀.

5 Nítorí èmi mọ̀ Olúwa tóbi,

àti Olúwa gbogbo òrìṣà lọ.

6 Olúwa ṣe ohunkóhun ó ú,

̀run àti ayé,

Òkun àti ̀gbun gbogbo.

7 Ó ìkùùkuu gòkè láti òpin ilẹ̀ :

ó mọ̀nàmọ́fún òjò:

ó ń afẹ́fẹ́ ti inú ilẹ̀ ìṣúra rẹ̀ .

8 Ẹni ó kọlu àwọn àkọ́Ejibiti,

àti ti ènìyàn àti ti ẹranko.

9 Ẹni ó rán iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu àárín rẹ̀, ìwọ Ejibiti,

ara Farao àti ara àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ gbogbo.

10 Ẹni ó kọlu àwọn orílẹ̀-èdè púpọ̀,

ó pa àwọn alágbára ọba.

11 Sihoni, ọba àwọn ará Amori, àti Ogu,

ọba Baṣani, àti gbogbo ìjọba Kenaani:

12 Ó fi ilẹ̀ wọn fún ni ìní,

ìní fún Israẹli, ènìyàn rẹ̀.

13 Olúwa orúkọ rẹ dúró láéláé;

ìrántí rẹ Olúwa, láti ìrandíran.

14 135.14: Hb 10.30. Nítorí Olúwa yóò ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn rẹ̀,

yóò ṣe ìyọ́àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀.

15 Fàdákà òun wúrà ni èrè àwọn aláìkọlà,

iṣẹ́ ọwọ́ ènìyàn ni.

16 Wọ́n ẹnu, ṣùgbọ́n wọn le sọ̀rọ̀;

wọ́n ojú, ṣùgbọ́n wọn fi ríran.

17 Wọ́n etí, ṣùgbọ́n wọn fi gbọ́rọ̀;

bẹ́̀ ni si èémí kan ẹnu wọn.

18 Àwọn ń ṣe wọ́n dàbí wọn:

gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni olúkúlùkù ẹni ó gbẹ́kẹ̀ rẹ̀ wọn.

19 ̀yin ara ilé Israẹli, fi ìbùkún fún Olúwa,

̀yin ará ilé Aaroni, fi ìbùkún fún Olúwa.

20 ̀yin ará ilé Lefi, fi ìbùkún fún Olúwa;

̀yin ó bẹ̀Olúwa, fi ìbùkún fún Olúwa.

21 Olùbùkún ni Olúwa, láti Sioni ,

ń gbé Jerusalẹmu.

fi ìyìn fún Olúwa.

Veja também