Publicidade

Salmos 14

Fún adarí orin. Ti Dafidi.

1 14.1-3: Ro 3.10-12. 14.1-7: Sm 53.1-6. Aṣiwèrè nínú ọkàn rẹ̀ ,

"Ko Ọlọ́run."

Wọ́n díbàjẹ́, iṣẹ́ wọn burú;

ẹnìkan yóò ṣe rere.

2 Olúwa bojú wolẹ̀ láti ̀run

lórí àwọn ọmọ ènìyàn

bóyá ó le ẹni òye ,

ẹnikẹ́ni ń Ọlọ́run.

3 Gbogbo wọn ti yípadà, gbogbo wọn ti díbàjẹ́;

ṣí ẹni ó ń ṣe rere,

ẹnìkan.

4 Ǹjẹ́ olùṣe búburú ha ìmọ̀?

Àwọn ó ń pa ènìyàn mi jẹ ẹní jẹun;

wọn pe Olúwa?

5 Wọ́n níbẹ̀, a mọ́lẹ̀ pẹ̀̀,

nítorí Ọlọ́run àwùjọ àwọn olódodo.

6 ̀yin olùṣe búburú da èrò àwọn tálákà ,

ṣùgbọ́n Olúwa ni ààbò wọn.

7 Ìgbàlà àwọn Israẹli yóò ti Sioni !

Nígbà Olúwa ìkólọ àwọn ènìyàn rẹ̀ padà,

jẹ́ Jakọbu ó yọ̀, inú Israẹli ó dùn!

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-