Publicidade

Salmos 18

Fún adarí orin. Ti Dafidi ìránṣẹ́ Olúwa ó kọ Olúwa, ̀rọ̀ orin ó kọ Olúwa fún ìdáǹdè kúrò lọ́wọ́ Saulu ̀rẹ̀. Ó .

1 Mo fẹ́ , Olúwa, agbára mi.

2 Olúwa ni àpáta àti odi mi, àti olùgbàlà mi;

Ọlọ́run mi ni àpáta mi, ẹni mo fi ṣe ibi ìsádi mi.

Òun ni àpáta ààbò àti ìwo ìgbàlà mi àti ibi ìsádi mi.

3 Mo pe Olúwa, ẹni ìyìn yẹ fún,

a ó gbà lọ́wọ́ àwọn ̀à mi.

4 Ìrora ikú mi ,

àti ìṣàn omi àwọn ènìyàn búburú dẹ́rùbà .

5 Okùn isà òkú mi ,

ìkẹ́kùn ikú dojúkọ .

6 Nínú ìpọ́njú mo pe Olúwa;

mo sọkún Olúwa mi fún ìrànlọ́wọ́.

Láti inú tẹmpili rẹ̀, ó gbọ́ igbe mi;

ẹkún mi iwájú rẹ̀, inú etí rẹ̀.

7 Ayé wárìrì, ó tìtì,

ìpìlẹ̀ àwọn òkè gíga ṣídìí;

wọ́n wárìrì nítorí ó ń bínú.

8 Èéfín ti ihò imú rẹ̀ jáde ;

iná ajónirun ti ẹnu rẹ̀ jáde ,

̀yin iná jáde láti inú rẹ̀.

9 Ó pín àwọn ̀run, Ó jáde ;

àwọsánmọ̀ dúdú abẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀.

10 Ó gun orí kérúbù, ó ;

ó ń rábàbà lórí ìyẹ́ apá afẹ́fẹ́.

11 Ó fi òkùnkùn ṣe ibojì rẹ̀, ó fi ṣe ìbòrí ara rẹ̀

kurukuru òjò dúdú ojú ̀run.

12 Nípa ìmọ́lẹ̀ iwájú rẹ̀, àwọsánmọ̀ ṣíṣú dudu rẹ kọjá lọ

pẹ̀yìnyín àti ̀yín iná

13 Olúwa sán àrá láti ̀run ;

̀gá-ògo fọ ohun rẹ̀; yìnyín àti ̀yin iná.

14 Ó ta àwọn ọfà rẹ̀, ó àwọn ̀náà ,

ọfà mọ̀nàmọ́ńlá wọ́n .

15 A fi ìsàlẹ̀ àwọn òkun hàn,

a àwọn ìpìlẹ̀ ayé

nípa ìbáwí rẹ, Olúwa,

nípa fífún èémí ihò imú rẹ.

16 Ó sọ̀kalẹ̀ láti ibi gíga, ó mímú;

Ó jáde láti inú omi jíjìn.

17 Ó gbà kúrò lọ́wọ́ ̀mi alágbára,

láti ọwọ́ àwọn ̀, ti ó lágbára fún mi.

18 Wọ́n dojúkọ ọjọ́ ìpọ́njú mi;

ṣùgbọ́n Olúwa ni alátìlẹ́yìn mi.

19 Ó mi jáde sínú ibi ńlá;

Ó gbà nítorí ó inú dídùn mi.

20 Olúwa ti hùwà mi gẹ́gẹ́ òdodo mi;

gẹ́gẹ́ mímọ́ ọwọ́ mi, ó ti fi èrè fún mi.

21 Nítorí mo ti pa ̀Olúwa mọ́;

èmi ṣe búburú nípa yíyí padà kúrò lọ́dọ̀ Ọlọ́run mi.

22 Gbogbo òfin rẹ̀ ni ó níwájú mi;

èmi yípadà kúrò nínú ìlànà rẹ̀.

23 Mo ti jẹ́ aláìlẹ́bi níwájú rẹ̀;

mo pa ara mi mọ́ kúrò nínú ̀ṣẹ̀.

24 Olúwa san ̀san fún mi gẹ́gẹ́ òdodo mi;

gẹ́gẹ́ mímọ́ ọwọ́ mi níwájú rẹ̀.

25 Fún olóòtítọ́ ni ìwọ ó fi ara rẹ̀ hàn olóòtítọ́,

aláìlẹ́bi, ìwọ ó fi ara rẹ̀ hàn aláìlẹ́bi,

26 ọlọ́kàn mímọ́, ìwọ ó fi ara rẹ̀ hàn ọlọ́kàn mímọ́,

ṣùgbọ́n ọlọ́kàn-wíwọ́, ìwọ ó fi ara rẹ̀ hàn òǹrorò.

27 O pa onírẹ̀lẹ̀ mọ́,

ṣùgbọ́n ó rẹ àwọn ti ń gbéraga sílẹ̀.

28 Ìwọ, Olúwa, jẹ́ fìtílà mi

ó máa tàn; Ọlọ́run mi, òkùnkùn mi padà ìmọ́lẹ̀.

29 Pẹ̀ìrànlọ́wọ́ rẹ̀, èmi sáré tọ ogun lọ;

pẹ̀Ọlọ́run mi mo fo odi kan.

30 ó ṣe ti Ọlọ́run mi, ̀rẹ̀ ,

a ti rídìí ̀rọ̀ Olúwa

òun ni àpáta ààbò fún gbogbo àwọn ó fi ṣe ààbò.

31 Nítorí ta ni ṣe Ọlọ́run ṣe Olúwa?

Ta àpáta ṣe Olúwa wa?

32 Ọlọ́run ni ẹni ó fi agbára àmùrè

ó ̀mi .

33 Ó ṣe ẹsẹ̀ mi gẹ́gẹ́ bi ẹsẹ̀ abo àgbọ̀nrín;

ó jẹ́ ki n dúró lórí ibi gíga.

34 Ó kọ́ ọwọ́ mi ni ogun jíjà;

apá mi tẹ ọrùn idẹ.

35 Ìwọ fi asà ìṣẹ́gun rẹ̀ fún mi,

ọwọ́ ̀tún rẹ̀ gbé dúró;

àti ìwà pẹ̀lẹ́ rẹ̀ sọ di ńlá.

36 Ìwọ sọ ìrìn ẹsẹ̀ mi di ńlá ìsàlẹ̀ mi,

kókó-ẹsẹ̀ mi ṣe yẹ̀.

37 Èmi lépa àwọn ̀mi, èmi wọn

èmi padà lẹ́yìn wọn títí a fi run wọ́n.

38 Èmi wọn ọgbẹ́ wọn ko fi le è dìde;

wọ́n ṣubú abẹ́ ẹsẹ̀ mi.

39 Nítorí ìwọ fi agbára àmùrè fún ogun náà;

ìwọ ti àwọn ó dìde si tẹríba abẹ́ ẹsẹ̀ mi.

40 Ìwọ ̀yìn àwọn ̀padà mi

èmi pa àwọn ó kórìíra mi run.

41 Wọ́n kígbe fún ìrànlọ́wọ́, ṣùgbọ́n ẹnìkan ó gbà wọ́n,

àní Olúwa, ṣùgbọ́n wọn lóhùn.

42 Mo wọ́n gẹ́gẹ́ eruku níwájú afẹ́fẹ́;

mo wọ́n síta gẹ́gẹ́ ẹrọ̀fọ̀.

43 Ìwọ ti gbà lọ́wọ́ ìkọlù àwọn ènìyàn;

Ìwọ ti fi ṣe olórí àwọn orílẹ̀-èdè.

Àwọn ènìyàn ti èmi mọ, yóò máa sìn ,

44 ni wéré ti wọ́n gbọ́ ohùn mi, wọ́n pa àṣẹ mi mọ́;

àwọn ọmọ àjèjì yóò tẹríba fún mi.

45 Àyà yóò àlejò;

wọn yóò fi ìbẹ̀jáde láti ibi kọ́lọ́fín wọn.

46 Olúwa láààyè! Olùbùkún ni àpáta mi!

Gbígbéga Ọlọ́run Olùgbàlà mi.

47 Òun ni Ọlọ́run ó ń gbẹ̀san mi,

ó ń ṣẹ́gun àwọn orílẹ̀-èdè ó abẹ́ mi,

48 ó pa mọ́ kúrò lọ́wọ́ àwọn ̀.

Ìwọ gbé mi ga ju àwọn ̀ó dìde mi lọ;

lọ́wọ́ àwọn ènìyàn alágbára ni ìwọ ti gbà .

49 Títí láéláé, èmi yóò máa yìn ́ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, ìwọ Olúwa;

èmi yóò máa kọ orin ìyìn orúkọ rẹ.

50 Ó fún ọba rẹ̀ ni ìṣẹ́gun ńlá;

ó fi ìkáàánú àìṣẹ̀tàn fún ẹni àmì òróró rẹ̀,

fún Dafidi àti ìran rẹ̀ títí láé.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-