Publicidade

Salmos 20

Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi.

1 Olúwa ó gbóhùn rẹ ọjọ́ ìpọ́njú;

orúkọ Ọlọ́run Jakọbu ó dáàbò ́.

2 ó rán ìrànlọ́wọ́ , láti ibi mímọ́

ó ́ lẹ́yìn láti Sioni .

3 ó rántí gbogbo ẹbọ rẹ

ó gba ẹbọ sísun rẹ. Sela.

4 ó fi fún gẹ́gẹ́ bi ti èrò ọkàn rẹ

ó gbogbo ìmọ̀ rẹ ṣẹ.

5 Àwa yóò fún ayọ̀ nígbà o di aṣẹ́gun

àwa yóò gbé àsíá wa sókè orúkọ Ọlọ́run wa.

Olúwa ó gbogbo ìbéèrè rẹ̀ ṣẹ.

6 Nísinsin yìí, èmi mọ̀ ,

Olúwa pa ẹni àmì òróró rẹ̀ mọ́.

Yóò gbọ́ láti ̀run mímọ́ rẹ̀

pẹ̀agbára ìgbàlà ọwọ́ ̀tún rẹ̀.

7 Àwọn mìíràn gbẹ́kẹ̀ wọn kẹ̀kẹ́, àwọn mìíràn gbẹ́kẹ̀ wọn ẹṣin,

ṣùgbọ́n àwa gbẹ́kẹ̀orúkọ Olúwa Ọlọ́run wa.

8 Wọ́n wólẹ̀, eékún, wọ́n ṣubú,

ṣùgbọ́n àwa dìde, a dúró ṣinṣin.

9 Olúwa, fi ìṣẹ́gun fún ọba!

wa lóhùn nígbà a ń kígbe !

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-