Publicidade

Salmos 21

Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi.

1 Háà! Olúwa, ọba yóò yọ̀ nínú agbára rẹ,

àti ìgbàlà rẹ, yóò ti yọ̀ pẹ́ !

2 Nítorí ìwọ ti fi ìfẹ́ ọkàn rẹ̀ fún un,

bẹ́̀ ni ìwọ dùn ún ìbéèrè ẹnu rẹ̀. Sela.

3 Ìwọ ti fi àwọn ìbùkún oore ó ni ̀

ìwọ fi adé wúrà e orí.

4 Ó béèrè fún ìyè, ìwọ fi fún un,

àní ọjọ́ gígùn títí ayérayé.

5 Ògo rẹ̀ pọ̀ nípasẹ̀ ìṣẹ́gun o fi fún un;

ìwọ jẹ́ iyì ọláńlá rẹ̀ lára rẹ.

6 Dájúdájú, ìwọ ti fi ìbùkún ayérayé fún un:

ìwọ inú rẹ̀ dùn pẹ̀ayọ̀ ojú u rẹ̀.

7 Ọba ìgbẹ́kẹ̀nínú Olúwa;

nípasẹ̀ ìfẹ́ ̀gá-ògo í kùnà

yóò sípò padà.

8 Ọwọ́ rẹ yóò gbogbo àwọn ̀a rẹ ;

ọwọ́ ̀tún rẹ yóò àwọn o kórìíra rẹ .

9 Nígbà ìwọ yọ

ìwọ yóò wọn dàbí iná ìléru.

Olúwa yóò gbé wọn nínú ìbínú rẹ̀,

àti iná rẹ̀ yóò wọn run.

10 Ìwọ yóò pa ìrandíran wọn run kúrò lórí ilẹ̀,

àti irú-ọmọ wọn kúrò láàrín àwọn ọmọ ènìyàn.

11 o tilẹ̀ jẹ́ wọ́n ro èrò ibi

wọ́n ń pète ìwà ìkà, wọn yóò ṣe àṣeyọrí.

12 Nítorí ìwọ yóò wọn ̀yìn wọn padà

nígbà o pinnu láti ta wọ́n ọfà.

13 Gbígbéga ni ́ Olúwa, nínú agbára rẹ;

a ó kọrin, a ó yín agbára a rẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-