Publicidade

Salmos 24

Ti Dafidi. Saamu.

1 Ti Olúwa ni ilẹ̀, àti ̀kún rẹ̀,

ayé àti àwọn ó tẹ̀sínú rẹ̀;

2 nítorí ó fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ lélẹ̀ lórí òkun

ó gbé e kalẹ̀ lórí àwọn ìṣàn omi.

3 Ta ni yóò gun orí òkè Olúwa lọ?

Ta ni yóò dúró ibi mímọ́ rẹ̀?

4 Ẹni ó ọwọ́ mímọ́ àti àyà funfun,

ẹni gbé ọkàn rẹ̀ sókè asán

búra èké.

5 Òun ni yóò ìbùkún gbà láti ̀dọ̀ Olúwa,

àti òdodo lọ́wọ́ Ọlọ́run ìgbàlà rẹ̀.

6 Èyí ni ìran àwọn ń ṣe àfẹ́rẹ̀,

ń ṣe àfẹ́rẹ̀, Ọlọ́run Jakọbu. Sela.

7 gbé orí yín sókè, háà! ̀yin ̀;

á gbe yín sókè, ẹyin ìlẹ̀kùn ayérayé!

ọba ògo le è wọlé.

8 Ta ni ọba ògo náà?

Olúwa ó lágbára ó le,

Olúwa gan an, ó lágbára ogun.

9 Gbé orí yín sókè, ẹyin ̀;

a gbé e yín sókè, ̀yin ìlẹ̀kùn ayérayé,

Ọba ògo le è wọlé .

10 Ta ni Ọba ògo náà?

Olúwa àwọn ọmọ-ogun

Òun ni Ọba ògo náà. Sela.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-