Publicidade

Salmos 25

6 Rántí, Olúwa àánú àti ìfẹ́ ẹ̀ rẹ̀ ńlá,

torí pé wọ́n ti wà ní ìgbà àtijọ́.

7 Má ṣe rántí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ ìgbà èwe mi

tàbí ìrékọjá mi;

gẹ́gẹ́ bí i ìfẹ́ ẹ rẹ̀ rántí mi

nítorí tí ìwọ dára, Ìwọ! Olúwa.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-22_10-02-25-