Publicidade

Salmos 27

Ti Dafidi.

1 Olúwa ni ìmọ́lẹ̀ mi àti ìgbàlà mi;

ta ni èmi yóò bẹ̀?

Olúwa ni ibi ìsádi ̀mi,

̀ta ni yóò ?

2 Nígbà àwọn ènìyàn búburú kọjú ìjà mi

láti jẹ ẹran-ara mi,

àní àwọn ̀mi àti àwọn abínúkú mi,

wọn yóò kọsẹ̀, wọn yóò ṣubú.

3 ọmọ-ogun tilẹ̀ mi wọ́n dìde mi,

ọkàn mi yóò bẹ̀;

ogun tilẹ̀ dìde mi,

nínú èyí ni ọkàn mi yóò le.

4 Ohun kan ni mo béèrè lọ́dọ̀ Olúwa,

òhun ni èmi yóò máa kiri:

èmi ó le ilé Olúwa

ọjọ́ ayé mi gbogbo,

èmi: ó le kíyèsi ẹwà Olúwa,

èmi ó máa tẹmpili rẹ̀.

5 Nítorí ìgbà ìpọ́njú

òun yóò pa mọ́ nínú àgọ́ rẹ̀;

níbi ìkọ̀kọ̀ àgọ́ rẹ̀ ni òun yóò pa mọ́;

yóò gbé mi sókè lórí àpáta.

6 ìsinsin yìí, a ti gbé orí mi sókè

ga ju ti àwọn ̀mi lọ ó ;

èmi yóò ẹbọ nínú àgọ́ rẹ, ẹbọ ariwo àti ti ayọ̀;

èmi yóò kọrin àní orin dídùn Olúwa.

7 Gbọ́ ohùn mi nígbà ̀à ń , Olúwa,

ṣe àánú fún mi o mi lóhùn,

8 Ọkàn mi , "ojú u rẹ̀!"

Ojú rẹ, Olúwa, ni ti èmí ń .

9 ṣe fi ojú rẹ pamọ́ kúrò lọ́dọ̀ mi,

ṣe fi ìbínú ìránṣẹ́ rẹ ;

ìwọ o ti jẹ́ olùrànlọ́wọ́ mi,

ṣe fi sílẹ̀, ṣe kọ̀ ,

háà! Ọlọ́run ìgbàlà mi.

10 ìyá àti baba kọ̀ sílẹ̀,

Olúwa yóò tẹ́wọ́ gbà .

11 Kọ́ mi ̀rẹ, Olúwa,

o sìn mi lọ ̀ó tẹ́

nítorí àwọn ̀mi.

12 ṣe fi ìfẹ́ àwọn ̀mi lọ́wọ́,

nítorí àwọn ẹlẹ́rìí èké ti dìde mi,

wọ́n ìmí ìkà.

13 Èmi ìgbàgbọ́ ,

èmi yóò ìre Olúwa

ilẹ̀ alààyè.

14 Dúró de Olúwa;

ó jẹ alágbára, o ọkàn le

àní dúró de Olúwa.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-