Publicidade

Salmos 28

Ti Dafidi.

1 Ìwọ Olúwa,

mo pe àpáta mi.

ṣe kọ etí dídi mi.

ìwọ dákẹ́ mi,

èmí yóò dàbí àwọn ó lọ ̀gbun.

2 Gbọ́ ohùn ̀bẹ̀ mi fún àánú,

mo ṣe ń ́ fún ìrànlọ́wọ́,

mo ṣe gbé àwọn ọwọ́ mi sókè

Ibi Mímọ́ rẹ Jùlọ.

3 ṣe lọ pẹ̀ènìyàn búburú àti,

pẹ̀àwọn oníṣẹ́ ̀ṣẹ̀,

ń sọ̀rọ̀ àlàáfíà aládùúgbò wọn

ṣùgbọ́n ìwà ìkà ń bẹ nínú wọn.

4 San ̀san wọn gẹ́gẹ́ iṣẹ́ wọn

àti fún iṣẹ́ ibi wọn;

gba ̀san wọn gẹ́gẹ́ iṣẹ́ ọwọ́ wọn;

o san ̀san wọn ó ti tọ́.

5 Nítorí wọn ka iṣẹ́ Olúwa ,

tàbí àwọn iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀

òun ó rún wọn wọlẹ̀

yóò gbé wọn mọ́.

6 Alábùkún fún ni Olúwa!

Nítorí ó ti gbọ́ ohùn ̀bẹ̀ mi.

7 Olúwa ni agbára mi àti asà mi;

nínú rẹ̀ ni mo gbẹ́kẹ̀; àní, ó ràn lọ́wọ́.

Ọkàn mi gbé sókè fún ayọ̀

àní pẹ̀orin mi mo fi ọpẹ́ fún un.

8 Olúwa ni agbára àwọn ènìyàn rẹ̀

òun ni odi ìgbàlà àwọn ẹni àmì òróró rẹ̀.

9 Ìwọ gba àwọn ènìyàn rẹ , o bùkún àwọn ajogún rẹ;

di olùṣọ́-àgùntàn wọn, o gbé wọn lékè títí ayérayé.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-