Publicidade

Salmos 32

Ti Dafidi. Maskili.

1 Ìbùkún ni fún àwọn

a dárí ìrékọjá wọn ,

a bo ̀ṣẹ̀ wọn mọ́lẹ̀.

2 Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà

ẹni Olúwa ka ̀ṣẹ̀ rẹ̀ i lọ́rùn

àti nínú ̀ẹni ̀tàn.

3 Nígbà mo dákẹ́,

egungun mi di gbígbó dànù

nípa ìkérora mi gbogbo ọjọ́.

4 Nítorí ni ̀sán àti òru

ọwọ́ rẹ̀ wúwo mi lára;

agbára mi gbẹ tán

gẹ́gẹ́ ooru ̀̀rùn. Sela.

5 Èmi jẹ́wọ́ ̀ṣẹ̀ mi

àti èmi fi àìṣòdodo mi pamọ́.

Èmi , "Èmi yóò jẹ́wọ́

̀ṣẹ̀ mi fún Olúwa,"

ìwọ dárí

̀bi ̀ṣẹ̀ mi . Sela.

6 Nítorí náà jẹ́ gbogbo àwọn olódodo máa gbà àdúrà

ìgbà a ;

nítòótọ́ nígbà ìṣàn omi ńlá ru sókè,

wọn yóò ̀dọ̀ rẹ̀.

7 Ìwọ ni ibi ìpamọ́ mi;

ìwọ yóò pa mọ́ kúrò nínú ìyọnu;

ìwọ yóò fi orin ìgbàlà mi ka. Sela.

8 Èmi yóò kọ́ , èmi yóò fi ẹsẹ̀ rẹ ̀ìwọ yóò rìn

èmi yóò máa gbà ́ ìyànjú, èmi yóò máa fi ojú mi tọ́ .

9 ṣe dàbí ẹṣin tàbí ìbáaka,

òye

ẹnu ẹni a gbọdọ̀ fi ìjánu bọ̀,

wọn ba à súnmọ́ .

10 ̀pọ̀ ìkáàánú yóò fún ènìyàn búburú,

ṣùgbọ́n ìfẹ́ Olúwa ó dúró ṣinṣin

ni yóò àwọn ó ìgbẹ́kẹ̀nínú Olúwa .

11 yọ̀ nínú Olúwa, inú dídùn, ̀yìn olódodo;

máa kọrin, gbogbo ̀yìn àyà yín dúró ṣinṣin.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-