Publicidade

Salmos 34

Dafidi. Nígbà ó díbọ́n ẹni ń ṣe wèrè níwájú Abimeleki, ẹni ó e lọ, ó jáde lọ.

1 Èmi yóò máa fi ìbùkún fún Olúwa nígbà gbogbo;

ìyìn rẹ̀ yóò máa ẹnu mi títí láé.

2 Ọkàn yóò máa ṣògo nínú Olúwa;

jẹ́ àwọn onírẹ̀lẹ̀ gbọ́ inú wọn ó máa dùn.

3 Gbé Olúwa ga pẹ̀mi;

jẹ́ a jọ gbé orúkọ rẹ̀ lékè.

4 Èmi Olúwa, ó mi lóhùn;

Ó gbà kúrò nínú ìbẹ̀mi gbogbo.

5 Wọ́n ó, ìmọ́lẹ̀ mọ́ wọn;

ojú wọ́n.

6 Ọkùnrin olùpọ́njú kígbe, Olúwa gbóhùn rẹ̀;

ó gbà á kúrò nínú gbogbo ìpọ́njú rẹ̀.

7 Angẹli Olúwa àwọn ó bẹ̀rẹ̀

ó gbà wọ́n.

8 Tọ́ o i Olúwa dára;

ẹni ayọ̀ ni ọkùnrin náà ó gbẹ́kẹ̀ààbò nínú rẹ̀.

9 bẹ̀Olúwa, ̀yin ènìyàn rẹ̀ mímọ́,

nítorí àìní fún àwọn ó bẹ̀rẹ̀.

10 Àwọn ọmọ kìnnìún a máa ṣe aláìní ebi a máa pa wọ́n;

ṣùgbọ́n àwọn ó Olúwa yóò ṣe aláìní ohun ó dára.

11 , ̀yin ọmọ mi, fi etí mi;

èmi yóò kọ́ yín ̀Olúwa.

12 Ta ni nínú yín ń fẹ́ ìyè, ó ń fẹ́ ọjọ́ púpọ̀;

ó gbádùn ọjọ́ rere?

13 Pa ahọ́n rẹ̀ mọ́ kúrò nínú ibi

àti ètè rẹ̀ kúrò ̀tàn sísọ.

14 kúrò nínú ibi o ṣe rere;

àlàáfíà, o lépa rẹ̀.

15 Ojú Olúwa ń bẹ lára àwọn olódodo;

etí i rẹ̀ ṣí ẹkún wọn.

16 Ojú Olúwa korò àwọn ń ṣe búburú;

láti ìrántí wọn kúrò lórí ilẹ̀.

17 Nígbà olódodo fún ìrànlọ́wọ́,

Olúwa a máa gbọ́, a yọ wọ́n jáde láti inú gbogbo wàhálà wọn.

18 Olúwa súnmọ́ etí ̀dọ̀ àwọn oníròbìnújẹ́ ọkàn;

ó gba irú àwọn í ṣe oníròra ọkàn .

19 Ìpọ́njú àwọn olódodo pọ̀,

ṣùgbọ́n Olúwa gbà wọ́n kúrò nínú gbogbo rẹ̀.

20 Ó pa gbogbo egungun wọn mọ́;

̀kan ó nínú wọn.

21 Ibi ni ó ikú ìkà ,

àti àwọn ó kórìíra olódodo ni yóò jẹ̀bi.

22 Olúwa ra ọkàn àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ padà;

̀kan nínú àwọn ó gbẹ́kẹ̀yóò jẹ̀bi.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-