Pular para o conteúdo
Publicidade

Salmos 35

Ti Dafidi.

1 Olúwa, gbógun ti àwọn ń gbóguntì ;

o kọ ojú ìjà àwọn ó ń mi í !

2 Di asà àti àpáta ,

o dìde fún ìrànlọ́wọ́ mi!

3 Fa idà àti ̀kọ̀ yọ

o dojúkọ àwọn ń mi.

Sọ fún ọkàn mi ,

"Èmi ni ìgbàlà rẹ."

4 wọn ó dààmú,

a ti àwọn ń lépa ọkàn mi lójú;

a wọn padà,

a dààmú àwọn ń gbèrò ìpalára mi.

5 Jẹ́ wọn dàbí ìyàngbò níwájú afẹ́fẹ́,

angẹli Olúwa ó máa wọn kiri.

6 Jẹ́ ̀wọn ó ṣókùnkùn, ó máa yọ́,

angẹli Olúwa ó máa lépa wọn!

7 Nítorí , àìnídìí ni wọ́n dẹ àwọ̀n wọn sílẹ̀ fún mi,

àìnídìí ni wọ́n wa kòtò sílẹ̀ fún ọkàn mi.

8 ìparun ó orí rẹ̀ òjijì.

Àwọ̀n rẹ̀ ó dẹ, ó òun tìkára rẹ̀;

wọn ṣubú sínú kòtò ìparun ara rẹ̀.

9 Nígbà náà ni ọkàn mi yóò yọ̀ nínú Olúwa,

àní, yóò máa yọ̀ nínú ìgbàlà rẹ̀.

10 Gbogbo egungun mi yóò ,

"Ta ni ó dàbí ì ìwọ Olúwa?

O gba tálákà lọ́wọ́ àwọn ó lágbára ú lọ,

tálákà àti aláìní lọ́wọ́ ẹni ń fi ṣe ìkógun?"

11 Àwọn ẹlẹ́rìí èké dìde;

wọ́n ń bi mi ohun èmi mọ̀.

12 Wọ́n fi búburú san ìre fún mi;

láti sọ ọkàn mi di òfo.

13 Ṣùgbọ́n ó ṣe ti èmi ni, nígbà wọn ń ṣe àìsàn, mo wọ aṣọ ̀fọ̀;

mo fi àwẹ̀ pọ́n ara mi lójú.

Mo gba àdúrà pẹ̀ìtẹríba oókan àyà mi;

14 èmí ń lọ kiri ẹni ń ṣọ̀fọ̀

i ẹni fún ̀rẹ́ tàbí ̀gbọ́n mi ni.

Èmí tẹríba nínú ìbànújẹ́

ẹni ń ṣọ̀fọ̀ ìyà rẹ̀.

15 Ṣùgbọ́n nínú ìkọ̀sẹ̀ mi wọ́n yọ̀, wọ́n ara wọn jọ;

wọ́n ara wọn jọ mi; àní àwọn èmi mọ̀.

Wọ́n ya wọ́n dákẹ́.

16 àwọn àgàbàgebè ń ṣe ẹlẹ́àpèjẹ

wọ́n pa eyín wọn keke mi.

17 Yóò ti pẹ́ Olúwa, ìwọ yóò máa wọ́n lọ?

Yọ kúrò nínú ìparun wọn,

àní ̀ì mi kúrò lọ́wọ́ kìnnìún.

18 Nígbà náà ni èmi yóò ṣọpẹ́ fún nínú àjọ ńlá;

èmi yóò máa yìn ́ àwùjọ ̀pọ̀ ènìyàn.

19 35.19: Sm 69.4; Jh 15.25. ṣe jẹ́ àwọn ̀mi

ó yọ̀ lórí ì mi;

bẹ́̀ ni o ṣe àwọn ó kórìíra mi

àìnídìí máa ṣẹ́mi.

20 Nítorí wọn sọ ̀rọ̀ àlàáfíà,

ṣùgbọ́n wọ́n lóyún ̀rọ̀ ̀tàn

àwọn ènìyàn dídákẹ́ ilẹ̀ náà.

21 Wọ́n ya ẹnu wọn gbòòrò mi; wọ́n , "Háà! Háà!

Ojú wa ti i."

22 Ìwọ́ ti i Olúwa; ṣe dákẹ́!

Olúwa ṣe jìnnà mi!

23 Dìde! ru ara rẹ̀ sókè fún ààbò mi,

àti ̀ràn mi, Ọlọ́run mi àti Olúwa mi!

24 Ṣe ìdájọ́ mi, Olúwa Ọlọ́run mi, gẹ́gẹ́ òdodo rẹ,

o ṣe jẹ́ wọn ó yọ̀ lórí mi!

25 ṣe jẹ́ wọn nínú ara wọn , "Háà! A ti ohun ọkàn wa ń fẹ́!"

ṣe jẹ́ wọn ó , "A ti gbé e ."

26 ojú ó wọ́n,

wọn ó dààmú pọ̀,

àní àwọn ń yọ̀ ìyọnu mi

a fi ìtìjú àti àbùkù wọ̀ wọ́n aṣọ ń gbéraga mi.

27 Jẹ́ àwọn ó fẹ́ ìdáláre mi

fún ayọ̀ àti ìdùnnú;

wọn máa sọ ́ títí lọ, "gbígbéga ni Olúwa,

àlàáfíà ìránṣẹ́ rẹ̀."

28 Nígbà náà ni ahọ́n mi yóò máa sọ̀rọ̀ òdodo rẹ,

àti ìyìn rẹ gbogbo ọjọ́.

Veja também