Publicidade

Salmos 39

Fún adarí orin. Fún Jedutuni. Saamu Dafidi.

1 Mo , "Èmi yóò ṣọ́ ̀mi

èmi ó fi ahọ́n mi ṣẹ̀;

èmi yóò fi ìjánu ara mi ẹnu

níwọ̀n ìgbà ènìyàn búburú ń bẹ iwájú mi."

2 Mo fi ìdákẹ́ ya odi;

mo tilẹ̀ pa ẹnu mi mọ́ kúrò nínú ̀rọ̀ rere;

ìbànújẹ́ mi pọ̀ i.

3 Àyà mi gbóná inú mi.

Nígbà mo ń ṣàṣàrò, iná ràn;

nígbà náà ni mo fi ahọ́n mi sọ̀rọ̀:

4 "Olúwa, jẹ́ èmi ó mọ òpin mi,

àti ìwọ̀n ọjọ́ mi, ó ti

èmi o le mọ ìgbà níhìn-ín.

5 Ìwọ ti ṣe ayé mi

ìbú àtẹ́lẹwọ́,

ọjọ́ orí mi dàbí asán

iwájú rẹ.

Dájúdájú olúkúlùkù ènìyàn nínú

ìjókòó rere rẹ̀ jásí asán pátápátá. Sela.

6 "Nítòótọ́ ni olúkúlùkù ń rìn kiri òjìji.

Nítòótọ́ ni wọ́n ń yọ ara wọn lẹ́nu lórí asán;

wọ́n ń ọrọ̀ jọ,

wọn mọ ẹni yóò ko lọ.

7 "Ṣùgbọ́n ìsinsin yìí,

Olúwa,

kín ni mo ń dúró ?

Ìrètí ń bẹ ̀dọ̀ rẹ.

8 Gbà lọ́wọ́ ìrékọjá mi gbogbo.

o sọ di ẹni ̀gàn

àwọn ènìyàn búburú.

9 Mo dákẹ́ jẹ́́;

èmi ya ẹnu mi,

nítorí ìwọ ni ó ṣe é.

10 pàṣán rẹ kúrò ara mi;

èmí ṣègbé tán nípa lílù ọwọ́ rẹ.

11 Ìwọ fi ìbáwí kìlọ̀

fún ènìyàn nítorí ̀ṣẹ̀,

ìwọ a ẹwà rẹ parun

kòkòrò aṣọ;

nítòótọ́ asán ni ènìyàn gbogbo.

12 "Gbọ́ àdúrà mi, Olúwa,

o fetí igbe mi;

o ṣe di etí rẹ ẹkún mi.

Nítorí àlejò ni èmi lọ́dọ̀ rẹ,

àti àtìpó, gbogbo àwọn baba mi ti .

13 mi , èmi agbára,

èmi lọ kúrò níhìn-ín yìí,

àti èmi ó ṣe aláìsí."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-