Publicidade

Salmos 49

Fún adarí orin. Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu.

1 gbọ́ èyí, gbogbo ènìyàn!

fi etí i, gbogbo ̀yin aráyé.

2 Àti ẹni ó ga àti ẹni ó kéré

tálákà àti ọlọ́pẹ̀!

3 Ẹnu mi yóò sọ̀rọ̀ ọgbọ́n,

èrò láti ọkàn mi yóò òye

4 èmi yóò dẹ etí mi sílẹ̀ òwe,

èmi yóò ṣí ̀rọ̀ ìkọ̀kọ̀ mi sílẹ̀ lójú okùn dùùrù.

5 Èéṣe ti èmi yóò bẹ̀nígbà ọjọ́ ibi ?

Nígbà ̀ṣẹ̀ àwọn ajinnilẹ́sẹ̀ mi mi ,

6 àwọn o gbẹ́kẹ̀ọrọ̀ wọn,

wọn ń ṣe ìlérí ni ̀pọ̀lọpọ̀ ọrọ̀ wọn.

7 ọkùnrin ó ra ̀ẹnìkejì rẹ̀

padà tàbí san owó ìràpadà fún

Ọlọ́run.

8 Nítorí ìràpadà fún ẹni jẹ́ iyebíye

iye owó fún sísan rẹ̀,

9 ti ó máa títí ayé

láìrí isà òkú.

10 Nítorí ̀pọ̀ ènìyàn ọkùnrin ọlọ́gbọ́n ó ,

bẹ́̀ ni aṣiwèrè àti aláìlọ́gbọ́n pẹ̀ṣègbé

wọ́n fi ọrọ̀ wọn sílẹ̀ fún ẹlòmíràn.

11 Ibojì wọn ni yóò jẹ́ ilé wọn láéláé,

ibùgbé wọn láti ìrandíran,

wọn sọ orúkọ ilẹ̀ wọn orúkọ ara wọn.

12 Ṣùgbọ́n ọkùnrin o nínú ọlá dúró pẹ́

ó dàbí ẹranko ó ṣègbé.

13 Èyí ni òtítọ́ àwọn ènìyàn ó

gbàgbọ́ nínú ara wọn,

àti àwọn ń tẹ̀wọn,

ó gba ̀rọ̀ wọn. Sela.

14 Gẹ́gẹ́ àgùntàn ni a tẹ́ wọn sínú isà òkú

ikú yóò jẹun lórí wọn;

ẹni ó dúró ṣinṣin ni yóò,

jẹ ọba lórí wọn òwúrọ̀.

Ẹwà wọn yóò díbàjẹ́,

isà òkú ni ibùgbé ẹwà wọn.

15 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run yóò ra ọkàn mi padà

kúrò nínú isà òkú,

yóò gbé mi lọ sọ́dọ̀ òun fún rara rẹ̀.

16 ṣe bẹ̀nígbà ẹnìkan di ọlọ́rọ̀.

Nígbà ìyìn ilé rẹ̀ ń pọ̀ i.

17 Nítorí yóò ohun kan lọ nígbà ó ,

ògo rẹ̀ a sọ̀kalẹ̀ ipò òkú.

18 Nígbà ó láyé, ó súre fún ọkàn ara rẹ̀.

Àwọn ènìyàn yìn ́ nígbà ìwọ ṣe rere.

19 Òun yóò lọ ̀dọ̀ ìran àwọn baba rẹ̀

àwọn ki yóò ri ìmọ́lẹ̀ ayé.

20 Ọkùnrin ó ọlá òye dàbí ẹranko ó ṣègbé.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-