Publicidade

Salmos 50

Saamu ti Asafu.

1 Olúwa, Ọlọ́run alágbára,

sọ̀rọ̀ o pe ayé jọ

láti ìlà-oòrùn títí ìwọ̀ rẹ̀.

2 Láti Sioni , pípé ni ẹwà,

Ọlọ́run ń tan ìmọ́lẹ̀

3 Ọlọ́run ń bọ̀,

bẹ́̀ ni yóò dákẹ́,

iná yóò máa níwájú rẹ̀,

àti àyíká rẹ̀ ni ̀fúùfù líle yóò ti máa .

4 Yóò pe àwọn ̀run láti òkè jọ àti ayé,

o le máa ṣe ìdárò àwọn ènìyàn rẹ̀.

5 "àwọn ènìyàn mímọ́ jọ fún mi

àwọn wọn fi ẹbọ májẹ̀fún mi."

6 Àwọn ̀run yóò sọ̀rọ̀ òdodo rẹ̀,

nítorí Ọlọ́run fúnra rẹ̀ ni onídàájọ́.

7 "gbọ́, ̀yin ènìyàn mi, èmi yóò si sọ̀rọ̀, ìwọ Israẹli, èmi yóò jẹ́rìí :

èmi Ọlọ́run, àní Ọlọ́run rẹ.

8 Èmi yóò

nítorí àwọn ìrúbọ rẹ,

tàbí ọrẹ ẹbọ sísun rẹ, èyí ó níwájú mi

ìgbà gbogbo.

9 Èmí fẹ́ ó akọ màlúù láti inú ilé o kọ́ fún un,

tàbí o òbúkọ láti

inú agbo ẹran rẹ̀

10 nítorí gbogbo ẹran igbó ni tèmi

àti ẹran ̀sìn lórí ẹgbẹ̀rún (1,000) òkè.

11 Èmi mọ gbogbo ẹyẹ orí àwọn òkè ńlá

àti gbogbo ̀alààyè ó orí ilẹ̀ ni tèmi.

12 ebi tilẹ̀ ń pa , èmi yóò sọ fún ,

nítorí ayé ni tèmi àti ohun gbogbo

ó wa inú rẹ̀.

13 Ǹjẹ́ èmi yóò ha jẹ ẹran akọ màlúù tàbí

̀jẹ̀ òbúkọ?

14 "ẹbọ ọpẹ́ Ọlọ́run,

o san ̀jẹ́ rẹ fún ̀gá-ògo.

15 o ọjọ́ ìpọ́njú,

èmi yóò gbà ́, ìwọ yóò bu ọlá fún mi."

16 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run sọ fún àwọn, ènìyàn búburú:

"̀tọ́ o ìwọ fi ń tún àwọn ìlànà mi sọ,

tàbí ìwọ ń sọ májẹ̀mi ẹnu rẹ?

17 Ìwọ kórìíra àṣẹ mi,

ìwọ ṣá ̀rọ̀ apá kan.

18 Nígbà ìwọ olè, ìwọ dára pọ̀ mọ́ ọn,

ìwọ da ara rẹ àwọn alágbèrè.

19 Ìwọ lo ẹnu rẹ fún aburú,

ìwọ ń fi ahọ́n rẹ pète ̀tàn.

20 ìgbà gbogbo ìwọ ń sọ̀rọ̀ arákùnrin rẹ,

ìwọ ń ba orúkọ ọmọ ìyá rẹ jẹ́.

21 Àwọn nǹkan wọ̀nyí ni ìwọ ti ṣe, mo dákẹ́;

ìwọ mo jẹ́ irú kan náà ìrẹ,

ṣùgbọ́n èmi yóò ,

èmi yóò fi ̀sùn kàn ́ ojú ara rẹ.

22 "Ǹjẹ́ ìwọ ro èyí , ̀yin ó gbàgbé Ọlọ́run.

bẹ́̀ kọ́ èmi yóò fa yin ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ, láìsí ẹni yóò gbà yin sílẹ̀.

23 Ẹni ó ba ẹbọ ọrẹ-ọpẹ́ bu ọlá fún mi; ó tún ̀rẹ̀ ṣe,

èmi ó le fi ìgbàlà Ọlọ́run hàn án."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-