Publicidade

Salmos 51

4 , ìwọ nìkan ṣoṣo, ni mo dẹ́ṣẹ̀

ni mo ṣe búburú níwájú rẹ̀,

a láre nígbà ìwọ ń sọ̀rọ̀,

o le láìlẹ́bi, nígbà ìwọ ń ṣe ìdájọ́.

5 Nítòótọ́, nínú ̀ṣẹ̀ ni a ti mi,

nínú ̀ṣẹ̀ ni ìyá lóyún mi.

6 Nítòótọ́ ìwọ fẹ́ òtítọ́ inú;

ìwọ kọ́ mi ọgbọ́n ìhà ìkọ̀kọ̀.

7 Wẹ̀ pẹ̀ewé hísópù, èmi yóò mọ́;

fọ̀ , èmi yóò funfun ju yìnyín lọ.

8 Jẹ́ n gbọ́ ayọ̀ àti inú dídùn;

jẹ́ gbogbo egungun ìwọ ti run ó máa yọ̀.

9 Pa ojú rẹ̀ mọ́ kúrò nínú ̀ṣẹ̀ mi

o pa gbogbo àwọn àìṣedéédéé mi rẹ́.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-