Publicidade

Salmos 61

Fún adarí orin. Ohun èlò orin olókùn. Ti Dafidi.

1 Gbọ́ ẹkún mi, Ọlọ́run;

tẹ́àdúrà mi.

2 Láti òpin ayé ni èmi yóò ́,

mo nígbà àyà mi ń ṣàárẹ̀;

mi lọ ibi àpáta ó ga lọ.

3 Nítorí ìwọ ti jẹ́ ibi ààbò mi,

ilé ìṣọ́ agbára àwọn ̀.

4 Mo ń lépa láti máa gbé nínú àgọ́ rẹ títí láé

n ààbò níbi ìyẹ́ apá rẹ.

5 Nítorí ìwọ ti gbọ́ àwọn ̀jẹ́ mi, Ọlọ́run;

Ìwọ ti fún mi ogún àwọn ó bẹ̀orúkọ rẹ.

6 Jẹ́ ̀ọba ó gùn,

ọdún rẹ̀ fún ìrandíran.

7 ó máa jẹ ọba níwájú Ọlọ́run títí láé;

pèsè àánú àti òtítọ́ rẹ yóò máa ṣe ìtọ́rẹ.

8 Nígbà náà ni èmi ó máa kọrin ìyìn orúkọ rẹ títí láé

n san ̀jẹ́ mi ojoojúmọ́.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-