Publicidade

Salmos 63

Saamu ti Dafidi. Nígbà ó nínú aginjù Juda.

1 Ọlọ́run, ìwọ ni Ọlọ́run mi,

nígbà gbogbo ni mo ń ṣàfẹ́rẹ,

òǹgbẹ rẹ ń gbẹ ọkàn mi,

ara mi ,

ilẹ̀ gbígbẹ àti ilẹ̀ ń ṣàárẹ̀

níbi omi.

2 Èmi ti ibi mímọ́,

mo agbára àti ògo rẹ.

3 Nítorí ìfẹ́ rẹ dára ju ayé lọ,

ètè mi yóò fògo fún .

4 Èmi ó yìn ́ níwọ̀n ìgbà mo láààyè,

èmi ó gbé ọwọ́ sókè, èmi ó pe orúkọ rẹ.

5 A ó tẹ́ ọkàn mi lọ́rùn ọlọ́ràá oúnjẹ;

pẹ̀ètè ìyìn, ẹnu mi yóò yìn ́.

6 Nígbà mo rántí rẹ lórí ibùsùn mi;

èmi ń ronú rẹ títí ìṣọ́ òru.

7 Nítorí ìwọ ni ìrànlọ́wọ́ mi,

mo kọrin níbi òjìji ìyẹ́ apá rẹ.

8 Ọkàn :

ọwọ́ ̀tún rẹ gbé mi .

9 Àwọn ó ń ọkàn ni a ó parun;

wọn ó sọ̀kalẹ̀ lọ ìsàlẹ̀ ilẹ̀ ayé.

10 Wọn ó ti ọwọ́ idà ṣubú

wọn ó di jíjẹ fún kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀.

11 Ṣùgbọ́n ọba yóò yọ̀ nínú Ọlọ́run

ẹni ó fi orúkọ Ọlọ́run búra yóò ṣògo

ṣùgbọ́n ẹnu àwọn òpùrọ́ la ó pamọ́.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-