Publicidade

Salmos 73

Saamu ti Asafu.

1 Nítòótọ́ Ọlọ́run dára fún Israẹli,

fún àwọn ọlọ́kàn funfun.

2 Ṣùgbọ́n ó ṣe ti èmi, ẹsẹ̀ mi ti yẹ̀ tán;

ìrìn mi fẹ́rẹ̀ yọ̀ tán.

3 Nítorí èmi ń ṣe ìlara àwọn ń ṣe féfé

nígbà mo àlàáfíà àwọn ènìyàn búburú.

4 Wọn ṣe wàhálà;

ara wọn mókun wọn lágbára.

5 Wọn ìpín nínú àjàgà ń ṣẹlẹ̀ ènìyàn;

a pọ́n wọn lójú nípa ẹlòmíràn.

6 Ìgbéraga ni ̀ṣọ́ ọrùn wọn;

ìwà ipá wọ́n mọ́lẹ̀ aṣọ.

7 Láti inú ọkàn àrékérekè ni àìṣòdodo ti ;

̀ọkàn búburú wọn òdínwọ̀n.

8 Wọn ń ṣẹ̀sín, wọn ń sọ̀rọ̀-òdì ti ìnilára,

wọ́n ń sọ̀rọ̀ láti ibi gíga.

9 Wọ́n ń gbé ̀wọn ̀run

ahọ́n wọn gba ipò ayé.

10 Nítorí náà àwọn ènìyàn wọn yípadà wọn

wọ́n mu omi ̀pọ̀lọpọ̀.

11 Wọ́n , "Báwo ni Ọlọ́run yóò ṣe mọ̀?

̀gá-ògo ha ìmọ̀ ?"

12 àwọn ènìyàn búburú ṣe nìyí,

ènìyàn asán, wọ́n ń pọ̀ ọrọ̀.

13 Nítòótọ́ nínú asán ni mo pa ọkàn mi mọ́;

nínú asán ni mo wẹ ọwọ́ mi àìlẹ́ṣẹ̀.

14 gbogbo ọjọ́ ni a ń yọ lẹ́nu;

a ń jẹ gbogbo òwúrọ̀.

15 mo , "Èmi ó báyìí,"

èmi ó ṣẹ̀ ìran àwọn ọmọ rẹ̀.

16 Nígbà mo gbìyànjú láti mọ èyí,

Ó jẹ́ ìnilára fún mi,

17 títí mo fi wọ ibi mímọ́ Ọlọ́run;

nígbà náà ni òye ìgbẹ̀yìn wọn mi.

18 Lóòtítọ́ ìwọ gbé wọn lórí ilẹ̀ yíyọ́

ìwọ wọ́n sílẹ̀ sínú ìparun.

19 Báwo a ti wọn lọ sínú ìdahoro yìí

ẹni ìṣẹ́kan!

Ìbẹ̀ni a fi ń run wọ́n pátápátá!

20 àlá nígbà ènìyàn ,

bẹ́̀ ni nígbà ìwọ dìde, Olúwa,

ìwọ yóò ṣe àbùkù àwòrán wọn.

21 Nígbà inú mi bàjẹ́

àti ọkàn mi ṣì korò,

22 mo jẹ́ aṣiwèrè àti aláìlóye;

mo jẹ́ ẹranko iwájú rẹ.

23 Síbẹ̀ mo pẹ̀rẹ nígbà gbogbo;

ìwọ di ọwọ́ ̀tún mi .

24 Ìwọ fi ìmọ̀ràn rẹ tọ́ mi

ìkẹyìn ìwọ ó mi lọ inú ògo.

25 Ta ni mo ̀run, ṣe ìwọ?

Àti ayé ohun mo fẹ́ lẹ́yìn rẹ.

26 Ara mi àti ọkàn mi le è kùnà

ṣùgbọ́n Ọlọ́run ni agbára ̀mi

àti ìpín mi títí láé.

27 Àwọn ó jìnnà yóò ṣègbé

ìwọ ti pa gbogbo wọn run;

ń ṣe àgbèrè kiri kúrò lọ́dọ̀ rẹ.

28 Ṣùgbọ́n ti èmi, ó dára láti súnmọ́ Ọlọ́run.

Èmi ti fi Olúwa Olódùmarè ṣe ààbò mi;

èmi ó máa sọ̀rọ̀ iṣẹ́ rẹ.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-