Publicidade

Salmos 8

Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ ti gittiti. Saamu ti Dafidi.

1 Olúwa, Olúwa wa,

orúkọ rẹ̀ ti ìyìn gbogbo ayé!

Ìwọ ti gbé ògo rẹ ga

ju àwọn ̀run lọ.

2 8.2: Mt 21.16. Láti ẹnu ọmọ ọwọ́ àti ọmọ ọmú

ni o ti yan ìyìn nítorí àwọn ̀rẹ,

láti pa àwọn ̀àti àwọn olùgbẹ̀san lẹ́nu mọ́.

3 Nígbà mo ro ̀run rẹ,

iṣẹ́ ìka rẹ,

òṣùpá àti ìràwọ̀,

ìwọ gbé kalẹ̀,

4 ni ènìyàn ìwọ ń nípa rẹ̀,

àní ọmọ ènìyàn ìwọ ń ṣe ìtọ́rẹ̀?

5 Ìwọ ṣe é onírẹ̀lẹ̀ díẹ̀ ju Ọlọ́run lọ,

ìwọ e adé ògo àti ọlá.

6 Ìwọ un jẹ ọba lórí gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ rẹ;

ìwọ fi ohun gbogbo abẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀:

7 àwọn agbo àgùntàn àti àwọn màlúù,

àti ẹranko igbó,

8 ẹyẹ ojú ọrun,

àti ẹja inú Òkun,

àti ohun ń wẹ nínú ipa Òkun.

9 Olúwa, Olúwa wa,

orúkọ rẹ ti ìyìn gbogbo ayé!

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-