Publicidade

Salmos 82

Saamu ti Asafu.

1 Ọlọ́run ń ṣàkóso nínú ìpéjọpọ̀ ńlá,

ó ṣe ìdájọ́ láàrín àwọn "ọlọ́run òrìṣà".

2 "Yóò ti pẹ́ ìwọ yóò máa gbèjà àwọn aláìṣòdodo

ó ṣe ojú ìṣáájú àwọn ènìyàn búburú?

3 Gbèjà àwọn aláìlágbára àti aláìní baba;

ṣe ìtọ́̀tọ́ àwọn aláìní àti ẹni ìnilára.

4 Gba àwọn aláìlágbára àti aláìní;

gbà wọ́n kúrò lọ́wọ́ àwọn ènìyàn búburú.

5 "Wọn mọ̀ ohun kankan,

wọn lóye ohun kankan.

Wọn ń rìn kiri nínú òkùnkùn;

à si gbogbo ìpìlẹ̀ ayé.

6 "Mo , Ẹyin "Ọlọ́run òrìṣà";

̀yin gbogbo ọmọ ̀gá-ògo jùlọ.

7 Ṣùgbọ́n ̀yin ó ènìyàn lásán;

̀yin ó ṣubú ̀kan nínú ọmọ-aládé."

8 Dìde, Ọlọ́run, ṣe ìdájọ́ ayé,

nítorí gbogbo orílẹ̀-èdè ni ìní rẹ.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-