Publicidade

Salmos 86

Àdúrà ti Dafidi.

1 Gbọ́, Olúwa, o mi lóhùn,

nítorí mo jẹ́ tálákà àti aláìní.

2 Dáàbò ayé mi, nítorí a ti sọ́tọ̀ fún :

ìwọ ni Ọlọ́run mi,

gbà ìránṣẹ́ rẹ

ó gbẹ́kẹ̀.

3 Ṣàánú fún mi, Olúwa,

nítorí èmi ń ́ gbogbo ọjọ́.

4 ayọ̀ fún ìránṣẹ́ rẹ,

nítorí ìwọ, Olúwa,

ni mo gbé ọkàn sókè .

5 Ìwọ ń dáríjì, ìwọ dára, Olúwa,

ìwọ ṣàánú fún gbogbo àwọn ń ́.

6 Gbọ́ àdúrà mi, Olúwa;

tẹ́ẹkún mi fún àánú.

7 ọjọ́ ìpọ́njú mi èmi yóò ́,

nítorí ìwọ yóò mi lóhùn.

8 Nínú àwọn òrìṣà ẹni ó dàbí i rẹ, Olúwa:

àwọn iṣẹ́ a fiwé tìrẹ.

9 Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ìwọ

yóò láti jọ́sìn níwájú rẹ, Olúwa;

wọn ó ògo fún orúkọ rẹ̀.

10 Nítorí ìwọ tóbi, ìwọ ń ṣe ohun ìyanu;

ìwọ nìkan ni Ọlọ́run.

11 Kọ́ mi ̀rẹ, Olúwa,

èmi ó máa rìn nínú òtítọ́ rẹ;

fún mi ọkàn í yapa,

èmi ó ba bẹ̀orúkọ rẹ.

12 Èmi ó yìn ́, Olúwa Ọlọ́run mi, pẹ̀gbogbo ọkàn mi;

èmi ó fògo fún orúkọ rẹ títí láé.

13 Nítorí títóbi ni ìfẹ́ rẹ si mi;

ìwọ ti gbà kúrò nínú ̀gbun isà òkú.

14 Àwọn onígbèéraga ń dojúkọ , Ọlọ́run;

àti ìjọ àwọn alágbára ń

ọkàn mi kiri,

wọn fi ́ .

15 Ṣùgbọ́n ìwọ, Olúwa, jẹ́ aláàánú àti Ọlọ́run olójúrere,

Ó lọ́ra láti bínú, Ó pọ̀ ìfẹ́ àti òtítọ́.

16 Yípadà mi o ṣàánú fún mi;

fún àwọn ènìyàn rẹ agbára

o gba ̀dọ́mọkùnrin ìránṣẹ́bìnrin rẹ .

17 Fi àmì hàn fún rere,

àwọn ó kórìíra mi ri,

ojú wọ́n, nítorí ìwọ Olúwa

ni ó ti nínú.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-