Publicidade

Salmos 88

Orin. Saamu ti àwọn ọmọ Kora. Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ ti mahalati leannoti. Maskili ti Hemani ará Esra.

1 Olúwa, Ọlọ́run ó gbà ,

̀sán àti òru, mo kígbe sókè .

2 Jẹ́ àdúrà mi ó iwájú rẹ;

dẹ etí rẹ igbe mi.

3 Nítorí ọkàn mi kún fún ìpọ́njú

ọkàn mi súnmọ́ isà òkú.

4 A mọ́ àwọn wọ́n lọ ̀gbun ilẹ̀

èmi dàbí ọkùnrin ni agbára.

5 A sọ́tọ̀ pẹ̀àwọn òkú

ẹni a pa ó dùbúlẹ̀ ipò ikú,

ẹni ìwọ rántí mọ́,

ẹni a kúrò lára àwọn ìwọ ń tọ́.

6 Ìwọ ó fi kòtò jíjìn,

ibi ̀gbun ṣókùnkùn.

7 Ìbínú rẹ ṣubú mi gidigidi;

ìwọ ti fi àwọn ìjì rẹ borí mi.

8 Ìwọ gba ̀rẹ́ mi ó súnmọ́ mi kúrò lọ́wọ́ mi

ìwọ sọ mi di ìríra wọn.

A mi mọ́, èmi le è jáde;

9 ojú mi káàánú nítorí ìpọ́njú.

Mo kígbe ́, Olúwa, gbogbo ọjọ́;

mo na ọwọ́ mi jáde .

10 Ìwọ ó fi iṣẹ́ ìyanu rẹ hàn fún òkú bi?

Àwọn òkú yóò ha dìde láti yìn ́ ?

11 A ó ha fi ìṣeun ìfẹ́ rẹ hàn ibojì ,

tàbí òtítọ́ rẹ ipò ìparun?

12 A ha mọ iṣẹ́ ìyanu rẹ òkùnkùn

àti òdodo rẹ ilẹ̀ ìgbàgbé?

13 Ṣùgbọ́n mo kígbe fún ìrànlọ́wọ́, Olúwa;

òwúrọ̀ ni àdúrà sọ́dọ̀ rẹ.

14 Olúwa, èéṣe ìwọ fi kọ̀

ìwọ fi ojú rẹ pamọ́ fún mi?

15 Láti ìgbà èwe mi, ìṣẹ́ ń ṣẹ́ mi,

èmi múra àti ;

nígbà ̀rẹ ń ,

èmi di gbére-gbère.

16 Ìbínú rẹ ti kọjá lára mi;

ìbẹ̀rẹ ti mi kúrò.

17 gbogbo ọjọ́ ni wọn mi ìkún omi;

wọ́n pátápátá.

18 Ìwọ ti ̀rẹ́ àti olùfẹ́ mi kúrò lọ́dọ̀ mi;

òkùnkùn jẹ́ ̀rẹ́ tímọ́tímọ́ mi.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-