Publicidade

Salmos 9

Fún adarí orin. ti ohun orin. "ti ikú ọmọ." Saamu ti Dafidi.

1 Èmi ó yìn ́, Olúwa, pẹ̀gbogbo ọkàn mi;

èmi ó sọ ti ìyanu rẹ gbogbo.

2 Inú mi yóò dùn, èmi yóò yọ̀ nínú rẹ;

èmi ó kọrin ìyìn orúkọ rẹ, Ìwọ ̀gá-Ògo jùlọ.

3 Àwọn ̀mi pẹ̀yìndà;

wọ́n kọsẹ̀ wọn ṣègbé níwájú rẹ.

4 Nítorí ìwọ ti di òtítọ́ àti ̀ràn mi ;

ìwọ ti jókòó lórí ìtẹ́ rẹ, láti ṣe ìdájọ́ òdodo.

5 Ìwọ ti orílẹ̀-èdè , Ìwọ ti pa ẹni búburú run;

Ìwọ ti yọ orúkọ wọn kúrò láé àti láéláé.

6 Ìparun àìlópin ti borí àwọn ̀,

ìwọ ti fa àwọn ìlú wọn tu;

àní ìrántí wọn ti ṣègbé.

7 Olúwa jẹ ọba títí láé;

ó ti gbé ìtẹ́ rẹ̀ kalẹ̀ fún ìdájọ́.

8 Òun yóò ṣe ìdájọ́ ayé òdodo;

yóò ṣe àkóso ènìyàn pẹ̀òdodo.

9 Olúwa ni ààbò fún àwọn a ni lára,

ibi ìsádi àkókò ìpọ́njú.

10 Àwọn ó mọ orúkọ rẹ yóò gbẹ́kẹ̀,

nítorí, Olúwa, kọ àwọn ń a sílẹ̀.

11 Kọ orin ìyìn Olúwa, o ń jẹ ọba Sioni;

kéde láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, ohun ó ṣe.

12 Nítorí ẹni ó ń gbẹ̀san ̀jẹ̀ rántí;

òun kọ ẹkún àwọn a pọ́n lójú.

13 Olúwa, wo àwọn ̀ṣe ń ṣe inúnibíni mi!

Ṣàánú, o gbé sókè kúrò ẹnu-ọ̀ikú,

14 èmi ó sọ ti ìyìn rẹ

ni ẹnu-ọ̀àwọn ọmọbìnrin Sioni

àti láti máa yọ̀ nínú ìgbàlà rẹ.

15 Àwọn orílẹ̀-èdè ti kòtò wọn ti gbẹ́;

ẹsẹ̀ wọn ni àwọ̀n wọ́n dẹ sílẹ̀ kọ́.

16 A mọ Olúwa nípa òdodo rẹ̀;

àwọn ènìyàn búburú ni a dẹ́kun nípa iṣẹ́ ọwọ́ wọn.

17 Àwọn ènìyàn búburú ni a ó isà òkú,

àti gbogbo orílẹ̀-èdè ó gbàgbé Ọlọ́run.

18 Ṣùgbọ́n àwọn aláìní ni a gbàgbé láéláé,

ìrètí àwọn ti ó tálákà ni a yóò gbàgbé láéláé.

19 Dìde, Olúwa, ṣe jẹ́ ènìyàn borí;

jẹ́ a ṣe ìdájọ́ àwọn orílẹ̀-èdè ni iwájú rẹ.

20 wọ́n pẹ̀ìpayà, Olúwa;

jẹ́ àwọn orílẹ̀-èdè mọ̀ ènìyàn lásán ni wọ́n. Sela.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-