Publicidade

Salmos 94

1 Olúwa Ọlọ́run ẹni ń gbẹ̀san,

Ọlọ́run ẹni ń gbẹ̀san.

2 Gbé ara rẹ sókè, ìwọ onídàájọ́ ayé;

san ̀san fún agbéraga

ohun ó yẹ wọ́n.

3 Báwo yóò ti pẹ́ ,

Olúwa

àwọn ẹni búburú

yóò kọ orin ayọ̀?

4 Wọ́n ń sọ̀rọ̀ ìgbéraga jáde;

gbogbo àwọn olùṣe búburú

kún fún ìṣògo.

5 Wọ́n fọ́ àwọn ènìyàn rẹ túútúú, Olúwa:

wọ́n pọ́n ilẹ̀ ìní rẹ̀ lójú.

6 Wọ́n pa àwọn opó àti àlejò,

wọ́n pa àwọn ọmọ aláìní baba.

7 Wọ́n sọ , "Olúwa i;

Ọlọ́run Jakọbu kíyèsi i."

8 Kíyèsi i, ̀yin aláìlóye nínú àwọn ènìyàn;

̀yin aṣiwèrè, nígbà wo ni ̀yin yóò lóye?

9 Ẹni ó gbin etí, ó ṣe aláìgbọ́ ?

Ẹni ó ojú?

Ó ha ṣe aláìríran ?

10 Ẹni ń orílẹ̀-èdè , ṣé tọ́ ni ṣọ́?

Ẹni ń kọ́ ènìyàn ha ṣàìní ìmọ̀ ?

11 94.11: 1Kọ 3.20. Olúwa mọ èrò inú ènìyàn;

ó mọ̀ asán ni wọ́n.

12 Ìbùkún ni fún ènìyàn náà

ìwọ , Olúwa,

ẹni ìwọ kọ́ nínú òfin rẹ,

13 Ìwọ gbà á kúrò nínú ọjọ́ ibi,

títí a ó fi wa ihò sílẹ̀ fún ẹni búburú.

14 Nítorí Olúwa kọ àwọn ènìyàn rẹ̀ sílẹ̀,

Òun kọ ilẹ̀ ìní rẹ̀ sílẹ̀.

15 Ìdájọ́ yóò padà òdodo,

àti gbogbo àwọn ọlọ́kàn

dídúró ṣinṣin yóò tẹ̀e lẹ́yìn.

16 Ta ni yóò dìde fún mi

àwọn olùṣe búburú?

Tàbí ta ni yóò dìde àwọn oníṣẹ́ ̀ṣẹ̀ fún mi?

17 ṣe Olúwa fún mi ìrànlọ́wọ́,

èmi fẹ́rẹ̀ máa gbé ilẹ̀ ó dákẹ́.

18 Nígbà mo sọ , "Ẹsẹ̀ mi ń yọ̀",

Olúwa, ìfẹ́ rẹ̀ ni ó lẹ́yìn.

19 Nígbà àníyàn ńlá nínú mi,

ìtùnú rẹ̀ ayọ̀ ọkàn mi.

20 Ìjọba ìbàjẹ́ ha kẹ́gbẹ́ pẹ̀rẹ

ẹni ń fi òfin mọ́ ìwà ìkà?

21 Wọ́n ara wọn jọ olódodo

wọ́n ń àwọn aláìṣẹ̀ lẹ́bi ikú.

22 Ṣùgbọ́n, Olúwa ti di odi alágbára mi,

àti Ọlọ́run mi ni àpáta nínú ẹni

mo ti ń gba ààbò.

23 Òun yóò san ̀san ibi wọn fún wọn

yóò pa wọ́n run nítorí búburú wọn

Olúwa Ọlọ́run wa yóò pa wọ́n run.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-