Publicidade

Salmos 96

1 96.1-13: 1Ki 16.23-33. kọrin tuntun Olúwa,

kọrin Olúwa gbogbo ayé.

2 kọrin Olúwa, yin orúkọ rẹ̀

sọ ti ìgbàlà rẹ̀ ọjọ́ ọjọ́.

3 sọ ti ògo rẹ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè

àti iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ láàrín gbogbo ènìyàn.

4 Nítorí títóbi Olúwa ẹni ìyìn tọ́ ;

òun o yẹ a bẹ̀ju gbogbo òrìṣà lọ.

5 Nítorí asán ni gbogbo àwọn òrìṣà orílẹ̀-èdè

ṣùgbọ́n Olúwa àwọn ̀run.

6 Ọlá àti ọláńlá iwájú rẹ̀

agbára àti ògo ibi mímọ́ rẹ̀.

7 fi fún Olúwa, ̀yin ìbátan ènìyàn,

fi agbára àti ògo fún Olúwa.

8 fi ògo ó tọ́ Olúwa fún un;

ọrẹ , àgbàlá rẹ̀.

9 máa sin Olúwa nínú ẹwà ìwà mímọ́ rẹ̀;

wárìrì níwájú rẹ̀ gbogbo ayé.

10 Sọ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, "Olúwa jẹ ọba."

A fi ìdí ayé múlẹ̀, ;

ẹni yóò fi òtítọ́ ṣe ìdájọ́ ènìyàn.

11 Jẹ́ àwọn ̀run ó yọ̀, ayé pariwo

jẹ́ pápá òkun ó pẹ̀ohun gbogbo ń bẹ nínú rẹ̀.

12 Jẹ́ oko kún fún ayọ̀, àti ohun gbogbo ń bẹ nínú rẹ̀;

nígbà náà ni gbogbo igi igbó yóò máa yọ̀.

13 Wọn yóò kọrin níwájú Olúwa,

nítorí ó ń bọ̀ , ó ń bọ̀ ṣe ìdájọ́ ayé.

Yóò fi òdodo ṣe ìdájọ́ ayé

àti ti àwọn ènìyàn ni yóò fi òtítọ́ rẹ̀ ṣe.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-