Publicidade

Salmos 106

1 Yin Olúwa! fi ìyìn fún

Olúwa, nítorí ó ṣeun.

fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí ó ṣeun,

nítorí ìfẹ́ rẹ̀ dúró láéláé.

2 Ta ni ó ròyìn iṣẹ́ agbára Olúwa,

ta sọ nípa ìyìn rẹ̀?

3 Ìbùkún ni fún àwọn ń pa ìdájọ́ mọ́?

Ẹni n ṣe ohun ó tọ́.

4 Rántí mi, Olúwa,

nígbà o fi ojúrere rẹ hàn,

ìhà mi nígbà ìwọ gbà wọ́n,

5 èmi ó jẹ ìgbádùn àlàáfíà àwọn ìwọ ti yàn,

èmi ó darapọ̀ mọ́ àwọn ènìyàn,

ìní rẹ láti jọ yìn ́ lógo.

6 Àwa ti dẹ́ṣẹ̀ gẹ́gẹ́ àwọn baba wa ti ṣe,

àwa ti ṣe ohun a,

a ti hùwà búburú.

7 Nígbà àwọn baba wa Ejibiti,

iṣẹ́ ìyanu rẹ wọn,

wọn rántí ̀pọ̀lọpọ̀ àánú rẹ,

gẹ́gẹ́ wọ́n ṣe ṣọ̀tẹ̀ níbi Òkun, àní níbi Òkun Pupa.

8 Ṣùgbọ́n o gbà wọ́n nítorí orúkọ rẹ

láti jẹ́ agbára ńlá rẹ di mọ̀.

9 O Òkun Pupa , ó gbẹ;

o wọn la ìbú aginjù.

10 O gbà wọ́n kúrò lọ́wọ́ àwọn ̀wọn,

láti ọwọ́ ̀ni o ti gbà wọ́n.

11 Omi ya lu àwọn ̀wọn;

bẹ́̀ ni èyí ó nínú wọn.

12 Nígbà náà wọn gba ìpinnu rẹ gbọ́

wọ́n kọrin ìyìn rẹ.

13 Ṣùgbọ́n wọn pẹ́ gbàgbé ohun o ṣe

wọn dúró gba ìmọ̀ràn rẹ.

14 Nínú aginjù ni wọ́n ṣe ìfẹ́kúfẹ̀́,

nínú aṣálẹ̀, wọ́n dán Ọlọ́run .

15 Nígbà náà, ó fún wọn ohun wọ́n béèrè fún

ṣùgbọ́n ó rán àìsàn búburú wọn.

16 Nínú ibùdó ni wọ́n ṣe ìlara Mose

pẹ̀Aaroni, ẹni ó jẹ́ mímọ́ Olúwa.

17 Ilẹ̀ la ẹnu ó gbé Datani

ó bo ẹgbẹ́ Abiramu mọ́lẹ̀.

18 Ọwọ́ iná yọ ẹgbẹ́ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀;

iná jo àwọn ènìyàn búburú.

19 Horebu wọ́n ṣe ẹgbọrọ màlúù

wọ́n sin òrìṣà a ṣe láti ara irin.

20 Wọ́n pa ògo wọn

àwòrán màlúù, ń jẹ koríko.

21 Wọ́n gbàgbé Ọlọ́run, ẹni ó gbà wọ́n

ẹni ó ti ṣe ohun ńlá Ejibiti,

22 iṣẹ́ ìyanu ilẹ̀ Hamu

àti ohun ̀ni ̀Òkun Pupa.

23 Bẹ́̀ ni, ó sọ , òun yóò pa wọ́n run

ṣe ti Mose, ó yàn,

ó dúró níwájú ̀náà

ó pa ìbínú rẹ̀ mọ́ láti pa wọ́n run mọ́.

24 Nígbà náà, wọ́n kẹ́gàn ilẹ̀ dídára náà

wọn gba ìlérí rẹ̀ gbọ́.

25 Wọ́n ń kùn nínú àgọ́ wọn

wọn gbọ́rọ̀ Olúwa.

26 Bẹ́̀ ni ó búra fún wọn nípa gbígbé ọwọ́ rẹ̀ sókè

òun jẹ́ wọn ṣubú nínú aginjù,

27 láti jẹ́ àwọn ọmọ rẹ̀ ṣubú lára orílẹ̀-èdè

láti fọ́n wọn káàkiri lórí ilẹ̀.

28 Wọ́n da ara wọn pọ̀ mọ́ Baali-Peori,

wọ́n ń jẹ ẹbọ a àwọn òkú òrìṣà,

29 wọ́n Ọlọ́run bínú pẹ̀ohun búburú wọn ń ṣe

àjàkálẹ̀-ààrùn jáde láàrín wọn.

30 Ṣùgbọ́n Finehasi dìde láti i,

àjàkálẹ̀-ààrùn náà dáwọ́ dúró lọ́gán.

31 A ka èyí òdodo fún un àti

fún àwọn ìrandíran ń bọ̀

32 Níbi omi Meriba, wọ́n Ọlọ́run nínú,

ohun búburú orí Mose nítorí wọn.

33 Nítorí wọ́n ṣọ̀tẹ̀ ̀Ọlọ́run.

̀rọ̀ àìdára ti ẹnu Mose .

34 Wọn pa àwọn ènìyàn run

gẹ́gẹ́ Olúwa ti sọ fún wọn,

35 Ṣùgbọ́n wọ́n dàpọ̀ mọ́ àwọn orílẹ̀-èdè,

wọ́n gbà láti ṣe àṣà wọn.

36 Wọ́n sin àwọn òrìṣà wọn

ó di ìkẹ́kùn fún wọn.

37 Wọ́n fi àwọn ọmọkùnrin wọn ẹbọ

àti àwọn ọmọbìnrin fún òrìṣà.

38 Wọ́n ta ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀,

̀jẹ̀ àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin wọ.

Wọ́n fi wọ́n ẹbọ ère Kenaani,

ilẹ̀ náà di àìmọ́ fún ̀jẹ̀.

39 Wọ́n fi ìṣe wọn sọ ara wọn di aláìmọ́,

wọ́n ṣe àgbèrè lọ pẹ̀iṣẹ́ wọn.

40 Nígbà náà ni Olúwa bínú àwọn ènìyàn rẹ̀

ó kórìíra àwọn ènìyàn ìní rẹ̀

41 Ó wọ́n àwọn orílẹ̀-èdè lọ́wọ́,

àwọn ̀wọn jẹ ọba lórí wọn.

42 Àwọn ̀wọn ń pọ́n wọn lójú

wọn wọn sìn lábẹ́ àṣẹ wọn.

43 ̀pọ̀ ìgbà òun gbà wọ́n,

síbẹ̀ wọ́n ń ṣọ̀tẹ̀ i

wọ́n ṣòfò dànù nínú ̀ṣẹ̀ wọn.

44 Ṣùgbọ́n ó kíyèsi wọn nítorí ìṣòro

nígbà ó gbọ́ ẹkún wọn,

45 ó rántí májẹ̀rẹ̀ nítorí wọn

Nítorí agbára ìfẹ́ rẹ̀, ó ṣàánú wọn.

46 Lójú gbogbo àwọn ó wọn ìgbèkùn

ó wọn àánú.

47 Gbà , Olúwa Ọlọ́run wa,

o ṣà jọ kúrò láàrín àwọn kèfèrí,

láti máa fi ọpẹ́ fún orúkọ mímọ́ rẹ

láti máa ṣògo nínú ìyìn rẹ.

48 Olùbùkún ni Olúwa,

Ọlọ́run Israẹli, láti ìrandíran.

Jẹ́ gbogbo ènìyàn ó , "Àmín!"

fi ìyìn fún Olúwa!

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-