Publicidade

Salmos 116

1 Èmi fẹ́ràn Olúwa, nítorí ó gbọ́ ohùn mi;

ó gbọ́ ẹkún mi fún àánú.

2 Nítorí ó etí rẹ̀ padà mi,

èmi yóò máa é ni wọ́n ìgbà mo láààyè.

3 Okùn ikú mi ,

ìrora isà òkú sórí mi;

ìyọnu àti ìbànújẹ́ borí mi.

4 Nígbà náà ni mo pe orúkọ Olúwa:

"Olúwa, èmi bẹ̀ ́, gba ọkàn mi!"

5 Olúwa oore-ọ̀fẹ́, ó òdodo;

Ọlọ́run wa kún fún àánú.

6 Olúwa pa àwọn ọlọ́kàn fífúyẹ́ mọ́

nígbà mo nínú àìní ńlá, ó gbà .

7 Padà, ìwọ ọkàn mi, ibi ìsinmi rẹ,

nítorí Olúwa ṣe dáradára .

8 Nítorí ìwọ, Olúwa, ti gba ọkàn mi

kúrò lọ́wọ́ ikú,

ojú mi kúrò lọ́wọ́ omijé,

àti ẹsẹ̀ mi kúrò lọ́wọ́ ìṣubú,

9 nítorí èmi yóò máa rìn níwájú Olúwa

ilẹ̀ alààyè.

10 Èmi gbàgbọ́; nítorí náà mo ,

"èmi ìpọ́njú púpọ̀".

11 Àti nínú ìdààmú mi mo ,

"Èké ni gbogbo ènìyàn".

12 ni èmi yóò san fún Olúwa

nítorí gbogbo rere rẹ̀ mi?

13 Èmi yóò gbé ago ìgbàlà sókè

èmi yóò máa pe orúkọ Olúwa.

14 Èmi yóò ìlérí mi ṣẹ Olúwa

ojú àwọn ènìyàn rẹ̀.

15 Iyebíye ojú Olúwa

àti ikú àwọn ẹni mímọ́ rẹ̀.

16 Olúwa, nítòótọ́ ìránṣẹ́ rẹ ni mo jẹ́;

èmi ni ìránṣẹ́ rẹ, ọmọ ìránṣẹ́bìnrin rẹ;

ó ti mi sílẹ̀ nínú ìdè mi.

17 Èmi yóò ẹbọ ọpẹ́

èmi yóò pe orúkọ Olúwa.

18 Èmi yóò ìlérí mi sẹ Olúwa

ojú gbogbo àwọn ènìyàn rẹ̀,

19 nínú àgbàlá ilé Olúwa

àárín rẹ̀, ìwọ Jerusalẹmu.

yin Olúwa.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-