Publicidade

Salmos 119

1 Ìbùkún ni fún àwọn ẹni ̀wọn láìlẹ́ṣẹ̀,

ẹni í rìn ìbámu pẹ̀òfin Olúwa.

2 Ìbùkún ni fún àwọn ẹni ń pa òfin rẹ̀ mọ́

wọn ń a pẹ̀gbogbo ọkàn wọn.

3 Wọn ṣe ohun dára;

wọ́n rìn ̀rẹ̀.

4 Ìwọ ti la ìlànà rẹ̀ sílẹ̀

a pa wọ́n mọ́ gidigidi.

5 ̀mi ìbá dúró ṣinṣin

láti máa pa òfin rẹ̀ mọ́!

6 Nígbà náà, ojú

nígbà mo ń kíyèsi àṣẹ rẹ̀ gbogbo.

7 Èmi yóò yìn ́ pẹ̀ọkàn ìdúró ṣinṣin

èmi ti kọ́ òfin òdodo rẹ̀.

8 Èmi yóò gbọ́rọ̀ àṣẹ rẹ̀,

ṣe kọ̀ sílẹ̀ pátápátá.

9 Báwo ni àwọn ̀dọ́ yóò ti ṣe pa ̀rẹ̀ mọ́?

Láti máa gbé ìbámu ̀rọ̀ rẹ.

10 Èmi pẹ̀gbogbo ọkàn mi

ṣe jẹ́ èmi yapa kúrò nínú àṣẹ rẹ.

11 Èmi ti pa ̀rọ̀ rẹ mọ́ ọkàn mi

èmi ba à ṣẹ̀ .

12 Ìyìn ni fún Olúwa;

kọ́ mi àṣẹ rẹ.

13 Pẹ̀ètè mi èmi tún ṣírò

gbogbo òfin ó láti ẹnu rẹ.

14 Èmi ń yọ̀ ̀̀rẹ,

ènìyàn ṣe ń yọ̀ nínú ọláńlá.

15 Èmi ń ṣe àṣàrò nínú ìlànà rẹ

èmi kíyèsi ̀rẹ.

16 Inú mi dùn àṣẹ rẹ;

èmi yóò gbàgbé ̀rẹ.

17 Ṣe rere ìránṣẹ́ rẹ, èmi yóò láààyè;

èmi yóò ṣe ìgbọ́ràn ̀rọ̀ rẹ.

18 La ojú mi èmi ríran

ohun ìyanu ó nínú òfin rẹ.

19 Àlejò èmi jẹ́ láyé,

ṣe pa àṣẹ rẹ mọ́ fún mi.

20 Ọkàn mi pòruurù pẹ̀ìfojúsọ́

nítorí òfin rẹ nígbà gbogbo.

21 Ìwọ fi àwọn agbéraga , àwọn a fi gégùn ún

ó ṣìnà kúrò nínú àṣẹ rẹ.

22 ̀gàn àti àbùkù kúrò lára mi,

nítorí èmi pa òfin rẹ mọ́.

23 ó tilẹ̀ jẹ́ àwọn alákòóso kójọpọ̀,

wọ́n ń sọ̀rọ̀ ìbàjẹ́ mi,

ṣùgbọ́n ìránṣẹ́ rẹ ń ṣe àṣàrò nínú àṣẹ rẹ.

24 Òfin rẹ ni dídùn inú mi;

àwọn olùbádámọ̀ràn mi.

25 Ọkàn lẹ̀ mọ́ erùpẹ̀;

ìwọ sọ di ààyè gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ rẹ.

26 Èmi tún ̀mi ṣírò ìwọ mi lóhùn;

kọ́ mi àṣẹ rẹ.

27 Jẹ́ n mọ ̀kọ́ ìlànà rẹ:

nígbà náà ni èmi yóò ṣe àṣàrò iṣẹ́ ìyanu rẹ.

28 Ọkàn mi ń ṣe àárẹ̀ pẹ̀ìbànújẹ́;

fi agbára fún mi gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ rẹ.

29 Pa mọ́ kúrò nínú ̀̀tàn

fún mi oore-ọ̀fẹ́ nípa òfin rẹ.

30 Èmi ti yan ̀òtítọ́

èmi ti gbé ọkàn mi òfin rẹ.

31 Èmi yára di òfin rẹ . Olúwa

ṣe jẹ́ ojú ó .

32 Èmi sáré ipa ̀àṣẹ rẹ,

nítorí ìwọ, ti ọkàn mi sílẹ̀.

33 Kọ́ mi, Olúwa, láti tẹ̀àṣẹ rẹ;

nígbà náà ni èmi yóò pa wọ́n mọ́ òpin.

34 Fún mi òye, èmi yóò pa òfin rẹ mọ́

èmi yóò máa kíyèsi i pẹ̀ọkàn mi.

35 Fi ipa ̀àṣẹ rẹ hàn ,

nítorí nínú rẹ̀ ni èmi inú dídùn.

36 ọkàn mi padà òfin rẹ

ó ṣe ojúkòkòrò mọ́.

37 ojú mi padà kúrò láti máa wo ohun asán:

pa ̀mi mọ́ gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ rẹ.

38 ìlérí rẹ sẹ ìránṣẹ́ rẹ,

nítorí òfin rẹ dára.

39 ̀gàn mi padà mo bẹ̀

nítorí ìdájọ́ rẹ dára.

40 Kíyèsi i, ọkàn mi ti ̀kọ́ rẹ!

Pa ayé mi mọ́ nínú òdodo rẹ.

41 Jẹ́ ìfẹ́ rẹ í kùnà mi, Olúwa,

ìgbàlà rẹ gẹ́gẹ́ ìpinnu rẹ.

42 Nígbà náà ni èmi yóò

ẹni ń sọ̀rọ̀ ̀gàn mi lóhùn,

nítorí èmi gbẹ́kẹ̀̀rọ̀ rẹ.

43 ṣe gba ̀rọ̀ òtítọ́ láti ẹnu mi

nítorí èmi ti gbé ìrètí mi sínú àṣẹ rẹ.

44 Èmi yóò máa gbọ́rọ̀ òfin rẹ nígbà gbogbo

láé àti láéláé.

45 Èmi yóò máa rìn káàkiri òmìnira,

nítorí èmi ti kígbe ̀kọ́ rẹ jáde.

46 Èmi yóò sọ̀rọ̀ òfin rẹ níwájú àwọn ọba

ojú yóò ,

47 nítorí èmi inú dídùn nínú àṣẹ rẹ

nítorí èmi ìfẹ́ wọn.

48 Èmi gbé ọwọ́ mi sókè nítorí àṣẹ rẹ, èyí èmi fẹ́ràn,

èmi ń ṣe àṣàrò òfin rẹ̀.

49 Rántí ̀rọ̀ rẹ ìránṣẹ́ rẹ,

nítorí ìwọ ti fún mi ìrètí.

50 Ìtùnú mi nínú ìpọ́njú mi ni èyí:

ìpinnu rẹ pa ayé mi mọ́.

51 Àwọn agbéraga fi ṣe ẹlẹ́láì dádúró,

ṣùgbọ́n èmi padà nínú òfin rẹ.

52 Èmi rántí àwọn òfin rẹ ìgbàanì, Olúwa,

èmi ìtùnú nínú wọn.

53 Ìbínú mímú ṣinṣin nítorí àwọn ẹni búburú,

wọ́n ti kọ òfin rẹ sílẹ̀.

54 Òfin rẹ ni ̀rọ̀ ìpìlẹ̀ orin mi

níbikíbi èmi ń gbé.

55 òru èmi rántí orúkọ rẹ, Olúwa,

èmi yóò pa òfin rẹ mọ́

56 nítorí mo

gba ̀kọ́ rẹ gbọ́.

57 Ìwọ ni ìpín mi, Olúwa:

èmi ti pinnu láti tẹríba ̀rọ̀ rẹ.

58 Èmi ti ojú rẹ pẹ̀gbogbo ọkàn mi:

fún mi oore-ọ̀fẹ́ gẹ́gẹ́ ìpinnu rẹ.

59 Èmi ti kíyèsi ̀mi

èmi ti gbé ìgbésẹ̀ mi òfin rẹ.

60 Èmi yóò yára, ń ni lọ́ra

láti gbọ́rọ̀ àṣẹ rẹ.

61 ó tilẹ̀ jẹ́ àwọn ẹni búburú pẹ̀okùn,

èmi gbàgbé òfin rẹ.

62 àárín ̀gànjọ́ òru èmi dìde láti fi ọpẹ́ fún

nítorí òfin òdodo rẹ.

63 Èmi jẹ́ ̀rẹ́ gbogbo àwọn ó bẹ̀rẹ,

gbogbo àwọn ń tẹ̀̀kọ́ rẹ.

64 Ayé kún fún ìfẹ́ rẹ, Olúwa,

kọ́ mi òfin rẹ.

65 Ṣe rere ìránṣẹ́ rẹ

gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ rẹ, Olúwa.

66 Kọ́ mi ìmọ̀ àti ìdájọ́ rere,

nítorí mo gbàgbọ́ nínú àṣẹ rẹ.

67 a pọ́n mi lójú èmi ti ṣìnà,

ṣùgbọ́n ni ìsinsin yìí èmi gbọ́rọ̀ ̀rọ̀ rẹ.

68 Ìwọ dára, ohun ìwọ ń ṣe rere ni;

kọ́ mi ìlànà rẹ.

69 ó tilẹ̀ jẹ́ àwọn agbéraga ti gbìmọ̀ èké ,

èmi pa ̀kọ́ rẹ mọ́ pẹ̀gbogbo ọkàn mi.

70 Ọkàn wọn yigbì àánú,

ṣùgbọ́n èmi inú dídùn nínú òfin rẹ.

71 Ó dára fún mi a pọ́n mi lójú

nítorí èmi kọ́ òfin rẹ.

72 Òfin ó jáde láti ẹnu rẹ ju iyebíye mi lọ

ó ju ẹgbẹ̀rún ẹyọ fàdákà àti wúrà lọ.

73 Ọwọ́ rẹ ni ó mi ó mọ ;

fún mi òye láti kọ́ àṣẹ rẹ.

74 Jẹ́ gbogbo àwọn ó bẹ̀rẹ máa yọ̀ nígbà wọ́n mi,

nítorí èmi ti ìrètí mi sínú ̀rọ̀ rẹ.

75 Èmi mọ, Olúwa, nítorí òfin rẹ òdodo ni,

àti òtítọ́ ni ìwọ pọ́n mi lójú.

76 ìfẹ́ rẹ í kùnà jẹ́ ìtùnú mi,

gẹ́gẹ́ ìpinnu rẹ ìránṣẹ́ rẹ.

77 Jẹ́ àánú rẹ ó tọ̀ , èmi ó ,

nítorí òfin rẹ jẹ́ ìdùnnú mi.

78 ojú ó ti àwọn agbéraga

nítorí wọn pa lára láìnídìí

ṣùgbọ́n èmi yóò máa ṣe àṣàrò nínú ̀kọ́ rẹ.

79 àwọn ó bẹ̀rẹ padà mi,

àwọn ó òye òfin rẹ.

80 Jẹ́ ọkàn mi láìlẹ́bi òfin rẹ,

ojú ó ṣe .

81 Ọkàn mi ń fojú ṣọ́nítorí ìgbàlà rẹ,

ṣùgbọ́n èmi ti fi ìrètí mi sínú ̀rọ̀ rẹ.

82 Ojú mi kùnà, pẹ̀wíwo ìpinnu rẹ;

èmi , "Nígbà wo ni ìwọ yóò nínú?"

83 ó tilẹ̀ jẹ́ èmi dàbí awọ-wáìnì lójú èéfín,

èmi gbàgbé ìlànà rẹ.

84 Báwo ni ìránṣẹ́ rẹ̀ yóò ṣe dúró pẹ́ ?

Nígbà wo ni ìwọ yóò àwọn

ń ṣe inúnibíni mi ?

85 Àwọn agbéraga wa ihò ìṣubú fún mi,

ó lòdì òfin rẹ.

86 Gbogbo àṣẹ rẹ yẹ ìgbẹ́kẹ̀;

ràn lọ́wọ́, nítorí ènìyàn ń ṣe inúnibíni mi láìnídìí.

87 Wọ́n fẹ́rẹ pa rẹ́ kúrò nínú ayé,

ṣùgbọ́n èmi kọ ̀kọ́ rẹ.

88 Pa ayé mi mọ́ gẹ́gẹ́ ìfẹ́ rẹ,

èmi yóò gba ̀ẹnu rẹ̀ gbọ́.

89 ̀rọ̀ rẹ, Olúwa, títí láé ni;

ó dúró ṣinṣin ̀run.

90 Òtítọ́ rẹ̀ ń lọ gbogbo ìran ìran;

ìwọ ti ayé, ó dúró ṣinṣin.

91 Òfin rẹ dúró di òní

nítorí ohun gbogbo ń sìn ́.

92 òfin rẹ̀ jẹ́ dídùn inú mi,

èmi ìbá ti ṣègbé nínú ìpọ́njú mi.

93 Èmi yóò gbàgbé ̀kọ́ rẹ láé,

nítorí nípa wọn ni ìwọ ti pa ayé mi mọ́.

94 Gbà , nítorí èmi jẹ́ tìrẹ

èmi ti ̀kọ́ rẹ.

95 Àwọn ẹni búburú dúró láti pa run,

ṣùgbọ́n èmi yóò kíyèsi ̀rẹ.

96 ohun pípé gbogbo èmi ti òpin;

ṣùgbọ́n àṣẹ rẹ aláìlópin ni.

97 Báwo ni èmi ti fẹ́ òfin rẹ !

Èmi ń ṣe àṣàrò nínú rẹ̀

gbogbo ọjọ́ pípẹ́ .

98 Àṣẹ rẹ mi gbọ́n ju àwọn ̀mi lọ,

nítorí wọ́n pẹ̀mi láé.

99 Èmi iyè inú ju gbogbo olùkọ́ mi lọ,

nítorí èmi ń ṣe àṣàrò nínú òfin rẹ.

100 Èmi ni òye ju àwọn àgbà lọ,

nítorí mo gba ̀kọ́ rẹ.

101 Èmi ti pa ẹsẹ̀ mi mọ́ nínú gbogbo ̀ibi

nítorí èmi gba ̀rọ̀ rẹ.

102 Èmi kúrò nínú òfin rẹ,

nítorí ìwọ fúnra rẹ̀ ni ó kọ́ mi.

103 Báwo ni ̀rọ̀ rẹ̀ ṣe dùn mọ́ mi lẹ́nu ,

ó dùn ju oyin lọ ẹnu mi!

104 Èmi òye gbà nínú ̀kọ́ rẹ;

nítorí náà èmi kórìíra gbogbo ̀tọ́.

105 ̀rọ̀ rẹ ni fìtílà ẹsẹ̀ mi

àti ìmọ́lẹ̀ ipa ̀mi.

106 Èmi ti ṣe ìbúra èmi ti tẹnumọ́ ọn

èmi yóò máa tẹ̀òfin òdodo rẹ.

107 A pọ́n mi lójú gidigidi;

Olúwa, sọ mi di ààyè, gẹ́gẹ́ bi ̀rọ̀ rẹ

108 Olúwa, gba ìyìn àtinúwá ẹnu mi,

o kọ́ mi òfin rẹ̀.

109 ó tilẹ̀ jẹ́ ayé mi ni ọwọ́ mi nígbà gbogbo,

èmi gbàgbé òfin rẹ.

110 Àwọn ẹni búburú ti dẹ okùn sílẹ̀ fún mi,

ṣùgbọ́n èmi ṣìnà kúrò nínú ̀kọ́ rẹ.

111 Òfin rẹ ni ogún mi láéláé;

àwọn ni ayọ̀ ọkàn mi.

112 Ọkàn mi ti pípa òfin rẹ mọ́

láé òpin.

113 Èmi kórìíra àwọn ọlọ́kàn méjì,

ṣùgbọ́n èmi fẹ́ òfin rẹ.

114 Ìwọ ni ààbò mi àti asà mi;

èmi ti ìrètí mi sínú ̀rọ̀ rẹ.

115 kúrò lọ́dọ̀ mi, ̀yin olùṣe búburú,

èmi pa àṣẹ Ọlọ́run mi mọ́!

116 Gbé mi sókè gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ rẹ,

èmi ó

jẹ́ ojú ìrètí mi ó .

117 Gbé mi sókè, èmí yóò wa láìléwu;

nígbà gbogbo ni èmi yóò máa júbà òfin rẹ.

118 Ìwọ kọ gbogbo àwọn ó ṣìnà kúrò nínú òfin rẹ,

nítorí ̀tàn wọn asán ni.

119 Gbogbo àwọn ẹni búburú ayé ni ìwọ yọ kúrò i ìdàrọ́;

nítorí náà, èmi fẹ́ òfin rẹ̀.

120 Ara mi wárìrì ìbẹ̀nítorí rẹ̀:

èmi dúró ìbẹ̀òfin rẹ.

121 Èmi ti ṣe ohun i ṣe òdodo àti ̀tọ́:

ṣe fi sílẹ̀ fún àwọn ń ni lára.

122 àlàáfíà ìránṣẹ́ rẹ dájú:

ṣe jẹ́ àwọn agbéraga ni mi lára.

123 Ojú mi kùnà, fún wíwo ìgbàlà rẹ,

fún wíwo ìpinnu òdodo rẹ.

124 Ṣe pẹ̀ìránṣẹ́ rẹ gẹ́gẹ́ dídúró ṣinṣin ìfẹ́ rẹ

o kọ́ mi àṣẹ rẹ.

125 Èmi ni ìránṣẹ́ rẹ; fún mi òye

èmi òye òfin rẹ

126 Ó àsìkò fún láti ṣe iṣẹ́, Olúwa;

nítorí òfin rẹ ti fọ́.

127 Nítorí èmi fẹ́ràn àṣẹ rẹ

ju wúrà, àní ju wúrà dídára lọ,

128 nítorí èmi kíyèsi gbogbo ̀kọ́ òtítọ́ rẹ̀,

èmi kórìíra gbogbo ipa ̀búburú.

129 Òfin rẹ̀ ìyanu ni:

nítorí náà èmi gbà wọ́n gbọ́.

130 Ìṣípayá ̀rọ̀ rẹ̀ ìmọ́lẹ̀ ;

ó fi òye fún àwọn òpè.

131 Èmi ya ẹnu mi mo hẹlẹ,

nítorí èmi fojú ṣọ́àṣẹ rẹ.

132 padà mi o ṣàánú fún mi,

ìwọ ṣe máa ń ṣe nígbà gbogbo àwọn

ó fẹ́ràn orúkọ rẹ.

133 Fi ìṣísẹ̀ mi múlẹ̀ nínú ̀rọ̀ rẹ,

ṣe jẹ́ ̀ṣẹ̀ borí mi.

134 padà lọ́wọ́ aninilára ènìyàn,

èmi gbọ́ ̀kọ́ rẹ.

135 Jẹ́ ojú rẹ ó tàn ìránṣẹ́ rẹ lára

ó kọ́ mi àṣẹ rẹ.

136 Omijé sàn jáde ojú mi,

nítorí wọn gba òfin rẹ̀ jẹ́ òtítọ́.

137 Olódodo ni ìwọ Olúwa

ìdájọ́ rẹ dúró ṣinṣin.

138 Òfin ti ìwọ gbé kalẹ̀ jẹ́ òdodo:

wọ́n yẹ ni ìgbẹ́kẹ̀.

139 Ìtara mi ti pa run,

nítorí àwọn ̀mi fi ojú fo ̀rọ̀ rẹ .

140 Wọ́n ti dán ìpinnu rẹ pátápátá

ìránṣẹ́ rẹ fẹ́ràn wọ́n.

141 ó tilẹ̀ jẹ́ èmi jẹ́ onírẹ̀lẹ̀ àti ẹni ̀gàn

èmi ni gbàgbé ̀kọ́ rẹ.

142 Òdodo rẹ títí láé

òtítọ́ ni òfin rẹ̀.

143 Ìyọnu àti ìpọ́njú sórí mi,

ṣùgbọ́n àṣẹ rẹ ni inú dídùn mi.

144 Òfin rẹ jẹ́ òtítọ́ láé;

fún mi òye èmi .

145 Èmi kígbe pẹ̀gbogbo ọkàn mi:

mi lóhùn Olúwa,

èmi yóò gbọ́rọ̀ àṣẹ rẹ.

146 Èmi kígbe ́; gbà

èmi yóò pa òfin rẹ mọ́.

147 Èmi dìde ṣáájú àfẹ̀mọ́júmọ́ èmi fún ìrànlọ́wọ́;

èmi ti ìrètí mi sínú ̀rọ̀ rẹ.

148 Ojú mi ṣáájú ìṣọ́ òru,

nítorí èmi ṣe àṣàrò nínú ̀rọ̀ rẹ.

149 Gbọ́ ohùn mi ìṣọ̀kan pẹ̀ìfẹ́ rẹ:

pa ayé mi mọ́, Olúwa, gẹ́gẹ́ òfin rẹ.

150 Àwọn ń gbìmọ̀ ìlànà búburú tòsí,

ṣùgbọ́n wọ́n jìnnà òfin rẹ.

151 Síbẹ̀ ìwọ tòsí, Olúwa,

àti gbogbo àṣẹ rẹ jẹ́ òtítọ́.

152 Láti ọjọ́ pípẹ́ èmi ti kọ́ nínú òfin rẹ

ìwọ ti fi ìdí wọn múlẹ̀ láéláé.

153 Wo ìpọ́njú mi o gbà ,

nítorí èmi gbàgbé òfin rẹ.

154 Gba ẹjọ́ mi o padà;

pa ayé mi mọ́ gẹ́gẹ́ ìpinnu rẹ.

155 Ìgbàlà jìnnà àwọn ẹni búburú

nítorí wọn àṣẹ rẹ.

156 Ìyọ́rẹ̀ tóbi, Olúwa;

pa ayé mi mọ́ gẹ́gẹ́ òfin rẹ.

157 ̀pọ̀lọpọ̀ ni àwọn ̀wọ́n ń ṣe inúnibíni mi,

ṣùgbọ́n èmi ì yípadà kúrò nínú òfin rẹ.

158 Èmi wo àwọn ẹlẹ́tàn, inú mi bàjẹ́

nítorí wọn gba ̀rọ̀ rẹ gbọ́.

159 Wo èmi ṣe fẹ́ràn ̀kọ́ rẹ;

pa ayé mi mọ́, Olúwa, gẹ́gẹ́ ìfẹ́ rẹ.

160 Òtítọ́ ni gbogbo ̀rọ̀ rẹ;

gbogbo òfin òdodo rẹ láéláé ni.

161 Àwọn alákòóso ṣe inúnibíni mi láìnídìí,

ṣùgbọ́n ọkàn mi wárìrì ̀rọ̀ rẹ.

162 Èmi yọ̀ nínú ìpinnu rẹ

ẹni ó ìkógun púpọ̀.

163 Èmi kórìíra mo kọ èké ṣíṣe

ṣùgbọ́n mo fẹ́ràn òfin rẹ.

164 Èmi yìn ́ ìgbà méje lójúmọ́

nítorí òfin òdodo rẹ.

165 Àlàáfíà púpọ̀ fún àwọn ó ìfẹ́ òfin rẹ,

ṣí ohun ó wọn kọsẹ̀.

166 Èmi yóò dúró de ìgbàlà rẹ, Olúwa,

èmi yóò tẹ̀àṣẹ rẹ.

167 Èmi gba òfin rẹ gbọ́,

nítorí mo fẹ́ràn wọn púpọ̀púpọ̀.

168 Èmi ṣe ìgbọ́ràn ̀kọ́ rẹ àti òfin rẹ,

nítorí ìwọ mọ gbogbo ̀mi.

169 Jẹ́ igbe mi iwájú rẹ, Olúwa;

fún mi òye gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ rẹ.

170 Jẹ́ ̀bẹ̀ mi iwájú rẹ;

gbà gẹ́gẹ́ ìpinnu rẹ.

171 Ètè mi yóò sọ ìyìn jáde,

nítorí ìwọ kọ́ mi ìlànà rẹ.

172 Jẹ́ ahọ́n mi kọ orin ̀rọ̀ rẹ,

nítorí gbogbo àṣẹ rẹ jẹ́ òdodo.

173 Jẹ́ ọwọ́ rẹ ṣetán láti ràn lọ́wọ́,

nítorí èmi ti yan ̀kọ́ rẹ.

174 Èmi wo ̀fún ìgbàlà rẹ, Olúwa,

àti òfin rẹ jẹ́ dídùn inú mi.

175 Jẹ́ èmi láààyè ki èmi yìn ́,

o jẹ́ òfin rẹ mi dúró.

176 Èmí ti ṣìnà àgùntàn ó sọnù.

ìránṣẹ́ rẹ,

nítorí èmi gbàgbé àṣẹ rẹ.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-