Pular para o conteúdo
Publicidade

Salmos 119

9 Báwo ni àwọn ̀dọ́ yóò ti ṣe pa ̀rẹ̀ mọ́?

Láti máa gbé ìbámu ̀rọ̀ rẹ.

10 Èmi pẹ̀gbogbo ọkàn mi

ṣe jẹ́ èmi yapa kúrò nínú àṣẹ rẹ.

11 Èmi ti pa ̀rọ̀ rẹ mọ́ ọkàn mi

èmi ba à ṣẹ̀ .

12 Ìyìn ni fún Olúwa;

kọ́ mi àṣẹ rẹ.

13 Pẹ̀ètè mi èmi tún ṣírò

gbogbo òfin ó láti ẹnu rẹ.

14 Èmi ń yọ̀ ̀̀rẹ,

ènìyàn ṣe ń yọ̀ nínú ọláńlá.

15 Èmi ń ṣe àṣàrò nínú ìlànà rẹ

èmi kíyèsi ̀rẹ.

16 Inú mi dùn àṣẹ rẹ;

èmi yóò gbàgbé ̀rẹ.

Veja também