Publicidade

Salmos 120

Orin fún ìgòkè.

1 Èmi pe Olúwa nínú ìpọ́njú mi,

ó mi lóhùn.

2 Gbà , Olúwa, kúrò lọ́wọ́ ètè èké

àti lọ́wọ́ ahọ́n ̀tàn.

3 ni a fi fún ?

Àti ni a túnṣe fún ,

ìwọ ahọ́n ̀tàn?

4 Òun yóò pẹ̀ọfà mímú ológun,

pẹ̀̀yín iná igi ìgbálẹ̀.

5 Ègbé ni fún mi èmi ṣe àtìpó Meṣeki,

nítorí èmi gbé nínú àgọ́ ìlú Kedari!

6 Ó ti pẹ́ èmi ti ń gbé

láàrín àwọn ó kórìíra àlàáfíà.

7 Ènìyàn àlàáfíà ni ;

ṣùgbọ́n nígbà mo sọ̀rọ̀, ogun ni dúró fun wọn.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-